< Psalms 47 >

1 Fún adarí orin. Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Ẹ pàtẹ́wọ́, gbogbo ẹ̀yin ènìyàn ẹ hó sí Ọlọ́run pẹ̀lú orin ayọ̀ tó rinlẹ̀.
Oh ploskajte [s] svojimi rokami, vsa ljudstva, vzklikajte Bogu z glasom zmagoslavja.
2 Báwo ni Olúwa Ọ̀gá-ògo ti ní ẹ̀rù tó ọba ńlá lórí gbogbo ayé.
Kajti Gospod, najvišji, je strašen, on je veliki Kralj nad vso zemljo.
3 Ṣe ìkápá àwọn orílẹ̀-èdè lábẹ́ wa àwọn ènìyàn lábẹ́ ẹsẹ̀ wa
Ljudstva bo podjarmil pod nas in narode pod naša stopala.
4 Ó mú ilẹ̀ ìní wa fún wa, ọlá Jakọbu, ẹni tí ó fẹ́ wa.
Izbral nam bo našo dediščino, odličnost Jakoba, ki ga je ljubil. (Sela)
5 Ọlọ́run tó gòkè lọ tí òun tayọ̀, Olúwa ti òun ti ariwo ìpè.
Bog se je dvignil z vzklikom, Gospod z zvokom šofarja.
6 Ẹ kọrin ìyìn sí Ọlọ́run, ẹ kọrin ìyìn. Ẹ kọrin ìyìn sí ọba wa, ẹ kọrin ìyìn!
Prepevajte hvalnice Bogu, prepevajte hvalnice. Prepevajte hvalnice našemu Kralju, prepevajte hvalnice.
7 Nítorí Ọlọ́run ni ọba gbogbo ayé, ẹ kọrin ìyìn pẹ̀lú Saamu!
Kajti Bog je Kralj vse zemlje. Prepevajte hvalnice z razumevanjem.
8 Ọlọ́run jẹ ọba lórí gbogbo kèfèrí; Ọlọ́run jókòó lórí ìtẹ́ ìwà mímọ́ rẹ̀.
Bog kraljuje nad pogani. Bog sedi na prestolu svoje svetosti.
9 Àwọn aládé ayé kó ara wọn jọ gẹ́gẹ́ bí ènìyàn Ọlọ́run Abrahamu nítorí asà ayé ti Ọlọ́run ni, òun ni ó ga jùlọ.
Princi ljudstva so se zbrali skupaj, celó ljudstvo Abrahamovega Boga, kajti ščiti zemlje pripadajo Bogu, on je silno vzvišen.

< Psalms 47 >