< Psalms 45 >

1 Fún adarí orin. Tí ohun orin “Lílì.” Ti orin àwọn ọmọ Kora. Maskili. Orin ìgbéyàwó. Ọkàn mi mọ ọ̀rọ̀ rere gẹ́gẹ́ bí mo ṣe ń sọ ohun tí mo ti ṣe fún ọba ahọ́n mi ni kálámù ayára kọ̀wé.
Přednímu kantoru z synů Chóre, na šošannim, vyučující. Píseň o lásce. Vyneslo srdce mé slovo dobré, vypravovati budu písně své o králi, jazyk můj jako péro hbitého písaře.
2 Ìwọ yanjú ju àwọn ọmọ ènìyàn lọ: a da oore-ọ̀fẹ́ sí ọ ní ètè: nítorí náà ni Ọlọ́run ṣe bùkún fún ọ láéláé.
Krásnější jsi nad všecky syny lidské, rozlita jest i milost ve rtech tvých, proto že jest tobě požehnal Bůh až na věky.
3 Gba idà rẹ mọ́ ìhà rẹ, ìwọ alágbára jùlọ wọ ara rẹ ní ògo àti ọláńlá.
Připaš meč svůj na bedra, ó reku udatný, prokaž důstojnost a slávu svou.
4 Nínú ọláńlá rẹ, máa gẹṣin lọ ní àlàáfíà lórí òtítọ́, ìwà tútù àti òtítọ́; jẹ́ kí ọwọ́ ọ̀tún rẹ ṣe ohun ẹ̀rù.
A v té slávě své šťastně vyjížděj s slovem pravdy, tichosti a spravedlnosti, a dokáže pravice tvá hrozných věcí.
5 Jẹ́ kí ọfà mímú rẹ̀ dá ọkàn àwọn ọ̀tá ọba lu jẹ́ kí àwọn orílẹ̀-èdè ṣubú sí abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀.
Střely tvé jsou ostré, padati budou od nich před tebou národové, proniknou až k srdci nepřátel královských.
6 Ọlọ́run láé, àti láéláé ni ìtẹ́ rẹ, ọ̀pá aládé ìjọba rẹ, ọ̀pá aládé òtítọ́ ni.
Trůn tvůj, ó Bože, jest věčný a stálý, berla království tvého jestiť berla nejupřímější.
7 Ìwọ fẹ́ olódodo, ìwọ sì kórìíra ìwà búburú nígbà náà Ọlọ́run, Ọlọ́run rẹ ti yàn ọ́ ṣe olórí àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ, nípa fífi àmì òróró ayọ̀ kùn ọ́.
Miluješ spravedlnost, a nenávidíš bezbožnosti, protož pomazal tě, Bože, Bůh tvůj olejem veselé nad účastníky tvé.
8 Gbogbo aṣọ rẹ̀ ni ó ń rùn pẹ̀lú òjìá àti aloe àti kasia; láti inú ààfin tí a fi eyín erin ṣe orin olókùn tẹ́ẹ́rẹ́ mú inú rẹ̀ dùn.
Mirra, aloe a kassia, všecka roucha tvá voní z paláců, z kostí slonových vzdělaných, nad ty, jenž tě obveselují.
9 Àwọn ọmọbìnrin àwọn ọba wà nínú àwọn àyànfẹ́ rẹ̀, ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ ni ayaba náà gbé dúró nínú wúrà Ofiri.
Dcery králů jsou mezi vzácnými tvými, přístojíť i manželka tobě po pravici v ryzím zlatě.
10 Gbọ́ ìwọ ọmọbìnrin, ronú kí o sì dẹtí rẹ sí mi gbàgbé àwọn ènìyàn rẹ àti ilé baba rẹ.
Slyšiž, dcerko, a viz, a nakloň ucha svého, a zapomeň na lid svůj a na dům otce svého.
11 Bẹ́ẹ̀ ni ọba yóò fẹ́ ẹwà rẹ gidigidi nítorí òun ni olúwa rẹ kí ìwọ sì máa tẹríba fún un.
I zalíbí se králi tvá krása; onť jest zajisté Pán tvůj, protož skláněj se před ním.
12 Ọmọbìnrin ọba Tire yóò wá pẹ̀lú ẹ̀bùn àwọn ọkùnrin ọlọ́rọ̀ yóò máa wá ojúrere rẹ̀.
Tuť i Tyrští s dary, před oblíčejem tvým kořiti se budou bohatí národové.
13 Gbogbo ògo ni ti ọmọbìnrin ọba ní àárín ilé rẹ̀, iṣẹ́ wúrà ọnà abẹ́rẹ́ ní aṣọ rẹ̀.
Všecka slavná jest dcera královská u vnitřku, roucho zlatem vytkávané jest oděv její.
14 Nínú aṣọ olówó iyebíye ni a mú un tọ́ ọba wá, àwọn wúńdíá ẹgbẹ́ rẹ̀ tẹ̀lé e, wọ́n sí mú un tọ̀ ọ́ wá.
V rouše krumpovaném přivedena bude králi, i panny za ní, družičky její, přivedeny budou k tobě.
15 Wọ́n sì mú un wá pẹ̀lú ayọ̀ àti inú dídùn wọ́n sì wọ ààfin ọba.
Přivedeny budou s radostí velikou a plésáním, a vejdou na palác královský.
16 Ọmọ rẹ̀ ni yóò gba ipò baba rẹ̀ ìwọ yóò sì fi wọ́n joyè lórí ilẹ̀ gbogbo.
Místo otců svých budeš míti syny své, kteréž postavíš za knížata po vší zemi.
17 Èmí yóò máa rántí orúkọ rẹ̀ ní ìran gbogbo, nígbà náà ni orílẹ̀-èdè yóò yìn ọ́ láé àti láéláé.
V pamět uvoditi budu jméno tvé po všecky věky, pročež oslavovati tě budou národové na věky věků.

< Psalms 45 >