< Psalms 42 >
1 Fún adarí orin. Maskili ti àwọn ọmọ Kora. Bí àgbọ̀nrín ti ń mí hẹlẹ sí ipa odò omi, bẹ́ẹ̀ ni ọkàn mi ń mí hẹlẹ sí ọ Ọlọ́run.
Kwĩhoka Ũhonokio wa Mwathani. Thaburi ya Ariũ a Kora O ta ũrĩa thwariga ĩnyootagĩra tũrũũĩ twa maaĩ, no taguo ngoro yakwa ĩkũnyootagĩra, Wee Ngai.
2 Òùngbẹ Ọlọ́run ń gbẹ ọkàn mi, fún Ọlọ́run alààyè. Nígbà wo ni èmi ó lọ bá Ọlọ́run?
Ngoro yakwa nĩ Ngai ĩnyootagĩra, O we Mũrungu ũrĩa ũrĩ muoyo. Ĩ nĩ rĩ ngaathiĩ ngacemanie na Ngai?
3 Oúnjẹ mi ni omijé mi ní ọ̀sán àti ní òru, nígbà tí àwọn ènìyàn ń wí fún mi ní gbogbo ọjọ́ pé, “Ọlọ́run rẹ dà?”
Maithori makwa matuĩkĩte nĩmo irio ciakwa mũthenya o na ũtukũ, nao andũ manjũũragia mũthenya wothe atĩrĩ, “Ngai waku akĩrĩ ha?”
4 Nígbà tí mo bá rántí nǹkan yìí, èmi tú ọkàn mi jáde nínú mi: èmi ti bá ọ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn lọ, èmi bá wọn lọ sí ilé Ọlọ́run pẹ̀lú ohùn ayọ̀ àti ìyìn, pẹ̀lú ọ̀pọ̀ ènìyàn tí ń pa ọjọ́ mímọ́ mọ́.
Maũndũ maya ndĩmaririkanaga o ngĩitũrũraga ngoro yakwa: ngaririkana ũrĩa ndatwaranaga na kĩrĩndĩ, ndongoretie mũtongoro nginya nyũmba-inĩ ya Ngai, tũkĩanagĩrĩra na gĩkeno na tũgĩcookagia ngaatho, ndĩ kĩrĩndĩ-inĩ hĩndĩ ya ciathĩ.
5 Èéṣe tí o fi ń rẹ̀wẹ̀sì, ìwọ ọkàn mi? Èéṣe tí ara rẹ kò fi lélẹ̀ nínú mi? Ìwọ ṣe ìrètí ní ti Ọlọ́run, nítorí èmi yóò sá à máa yìn ín, Olùgbàlà mi àti Ọlọ́run mi.
Wee ngoro yakwa, ũkĩritũhĩirwo nĩkĩ? Ũrathĩĩnĩka ũguo nĩkĩ ũrĩ thĩinĩ wakwa? Wĩrĩgagĩrĩre Ngai, nĩgũkorwo no ndĩrĩmũgoocaga, o we Mũhonokia wakwa, na Ngai wakwa.
6 Ọlọ́run mi, ọkàn mi ń rẹ̀wẹ̀sì nínú mi: nítorí náà, èmi ó rántí rẹ láti ilẹ̀ Jordani wá, láti Hermoni láti òkè Mibsari.
Ngoro yakwa nĩnditũhĩre ĩrĩ thĩinĩ wakwa; nĩ ũndũ ũcio nĩngũkũririkana ndĩ bũrũri wa Jorodani, o kũu irĩma-inĩ cia Herimoni, kuuma Kĩrĩma-inĩ kĩa Mizari.
7 Ibú omi ń pe ibú omi nípa híhó omi ṣíṣàn rẹ̀ gbogbo rírú omi àti bíbì omi rẹ̀ bò mí mọ́lẹ̀.
Ndia ĩmwe nĩĩreta ndia ĩrĩa ĩngĩ na mũgambo wa mũrurumo wa ndururumo ciaku cia maaĩ; makũmbĩ maku mothe o na ndiihũ nĩciũkĩte, ikaahubanĩria.
8 Ní ọ̀sán ní Olúwa ran ìfẹ́ rẹ̀, àti ni àṣálẹ́ ni orin rẹ̀ wà pẹ̀lú mi àdúrà sí Ọlọ́run ayé mi.
Mũthenya-rĩ, Jehova nĩarĩathagĩrĩra wendo wake harĩ niĩ, na ũtukũ nĩ rwĩmbo ndĩrĩmũinagĩra, rũrĩ ihooya rĩa kũhooya Mũrungu wa muoyo wakwa.
9 Èmi wí fún Ọlọ́run àpáta mi, “Èéṣe tí ìwọ fi gbàgbé mi? Èéṣe tí èmi o fi máa rìn nínú ìbànújẹ́, nítorí ìnilára ọ̀tá?”
Njũũragia Mũrungu, o we rwaro rwakwa rwa Ihiga, atĩrĩ, “Ũriganĩirwo nĩ niĩ nĩkĩ? Ingĩthiĩ ngĩcakayaga nĩkĩ, nĩ ũndũ wa kũhinyĩrĩirio nĩ thũ?”
10 Bí ẹni pé idà egungun mi ni ẹ̀gàn tí àwọn ọ̀tá mi ń gàn mí, bí wọn ti ń béèrè ní gbogbo ọjọ́. “Níbo ni Ọlọ́run rẹ wà?”
Nĩ ta ngũhehenjwo mahĩndĩ makwa, rĩrĩa amuku akwa mekũnyũrũria, magatinda mũthenya wothe makĩnjũũria atĩrĩ, “Ngai waku akĩrĩ ha?”
11 Èéṣe tí ìwọ fi ń rẹ̀wẹ̀sì, ìwọ ọkàn mi? Èéṣe tí ara rẹ kò fi lélẹ̀ nínú mi? Fi ìrètí rẹ sínú Ọlọ́run, nítorí èmi yóò sì máa yìn ín, Òun ni Olùgbàlà mi àti Ọlọ́run mi.
Wee ngoro yakwa, ũkĩritũhĩirwo nĩkĩ? Ũrathĩĩnĩka ũguo nĩkĩ ũrĩ thĩinĩ wakwa? Wĩrĩgagĩrĩre Ngai, nĩgũkorwo no ndĩrĩmũgoocaga, o we Mũhonokia wakwa na Ngai wakwa.