< Psalms 41 >

1 Fún adarí orin. Saamu Dafidi. Ìbùkún ni fún ẹni tí ó ń ro ti aláìní: Olúwa yóò gbà á ní ìgbà ìpọ́njú.
Kathutkung: Devit Tamimathoe hanelah ka pouk pouh e tami teh a yawkahawi e doeh. Runae tueng nah ahni hah BAWIPA ni a hlout sak han.
2 Olúwa yóò dáàbò bò ó yóò sì pa ọkàn rẹ̀ mọ́: yóò bùkún fún un ní orí ilẹ̀ kò sì ní fi sílẹ̀ fún ìfẹ́ àwọn ọ̀tá rẹ̀.
BAWIPA ni a hlout sak vaiteh, a pasai han. A tarannaw koe poe hanlah na pasoung mahoeh.
3 Olúwa yóò gbà á lórí àkéte àìsàn rẹ̀ yóò sì mú un padà bọ̀ sípò kúrò nínú àìsàn rẹ̀.
A pataw teh sut a yan navah BAWIPA ni thapoe vaiteh, amae hmalah bout na thaw sak han.
4 Ní ti èmi, mo wí pé “Olúwa, ṣàánú fún mi; wò mí sàn, nítorí pé mo ti ṣẹ̀ sí ọ”.
BAWIPA na pahren haw, ka hringnae heh dam sak haw. Bangkongtetpawiteh, nang taranlahoi ka yon toe telah ka ti.
5 Àwọn ọ̀tá mi ń sọ̀rọ̀ mi nínú àrankàn, pé, “Nígbà wo ni yóò kú, ti orúkọ rẹ̀ yóò sì run?”
Ka tarannaw ni nâtuek maw a due vaiteh a min raphoe lah ao han telah, thoenae koelah dueng na dei awh.
6 Nígbàkígbà tí ẹnìkan bá wá wò mí, wọn ń sọ̀rọ̀ ẹ̀tàn, nígbà tí àyà rẹ̀ bá kó ẹ̀ṣẹ̀ jọ sí ara rẹ̀; nígbà tí ó bá jáde lọ yóò sì máa tàn án kálẹ̀.
Na tho sin nahaiyah laithoe duengdoeh a dei awh. A lungthin ni payonnae dueng hah a pâkhueng teh, alawilah a tâco nah tangkuem koe ouk a dei.
7 Àwọn ọ̀tá mi gbìmọ̀ papọ̀ nípa mi; èmi ni wọ́n ń gbìmọ̀ ibi sí,
Na kahmuhmanaw pueng ni kai taranlahoi arulawk a kâdei awh teh, kai pataw nahane dueng doeh a kâdei awh.
8 wọ́n wí pé, “Ohun búburú ni ó dì mọ́ ọn ṣinṣin àti ní ibi tí ó dùbúlẹ̀ sí, kì yóò dìde mọ́.”
Patawnae kathout ni a man toung dawkvah, atu sut a yan toe, thaw mahoeh toe telah a kâdei awh.
9 Pàápàá, ọ̀rẹ́ mi tímọ́tímọ́, ẹni tí mo gbẹ́kẹ̀lé, ẹni tí ó ń jẹ nínú oúnjẹ mi, tí gbé gìgísẹ̀ rẹ̀ sókè sí mi.
Ka hui kahawi, ka kâuep e, kaie rawca ka cat e niyah, kai taranlahoi a khokpaimai na tawm sin.
10 Ṣùgbọ́n ìwọ Olúwa, ṣàánú fún mi; gbé mi sókè, kí ń ba lè san fún wọn.
Hatei, Oe BAWIPA, ahnimouh moi ka pathung thai nahanlah, na pahren nateh, bout na thaw sak haw.
11 Èmi mọ̀ pé inú rẹ̀ dùn sí mi, nítorí ọ̀tá mi kò borí mi.
Hete kong dawk kai dawk na lunghawi doeh tie ka panue. Bangkongtetpawiteh, ka tarannaw ni na tâ awh hoeh.
12 Bí ó ṣe tèmi ni ìwọ dì mímú nínú ìwà òtítọ́ mi ìwọ sì gbé mi kalẹ̀ níwájú rẹ títí láé.
Kai teh pouknae kalan ka tawn dawkvah, na tawm nateh na hmalah pou na hrueng haw.
13 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, láé àti láéláé.
Isarel BAWIPA teh, a yungyoe hoi a yungyoe totouh pholen lah awm lawiseh. Amen hoi Amen.

< Psalms 41 >