< Psalms 41 >

1 Fún adarí orin. Saamu Dafidi. Ìbùkún ni fún ẹni tí ó ń ro ti aláìní: Olúwa yóò gbà á ní ìgbà ìpọ́njú.
Bulahan siya nga nagapalandong sa mga kabus: Si Jehova magaluwas kaniya sa adlaw sa kadautan.
2 Olúwa yóò dáàbò bò ó yóò sì pa ọkàn rẹ̀ mọ́: yóò bùkún fún un ní orí ilẹ̀ kò sì ní fi sílẹ̀ fún ìfẹ́ àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Si Jehova magabantay kaniya, ug magahatag kaniya ug kinabuhi, Ug mabulahan siya sa ibabaw sa yuta; Ug dili mo siya igatugyan sa kabubut-on sa iyang mga kaaway.
3 Olúwa yóò gbà á lórí àkéte àìsàn rẹ̀ yóò sì mú un padà bọ̀ sípò kúrò nínú àìsàn rẹ̀.
Si Jehova magapalig-on kaniya sa ibabaw sa higdaanan sa kasakit: Pagahumokon mo ang tibook niyang higdaanan diha sa iyang balatian.
4 Ní ti èmi, mo wí pé “Olúwa, ṣàánú fún mi; wò mí sàn, nítorí pé mo ti ṣẹ̀ sí ọ”.
Ako miingon: Oh Jehova, malooy ka kanako: Ayuhon mo ang akong kalag; kay nakasala ako batok kanimo.
5 Àwọn ọ̀tá mi ń sọ̀rọ̀ mi nínú àrankàn, pé, “Nígbà wo ni yóò kú, ti orúkọ rẹ̀ yóò sì run?”
Ang akong mga kaaway nagapumulong ug dautan batok kanako, nga nagaingon: Anus-a ba siya mamatay, ug ma-hanaw ang iyang ngalan?
6 Nígbàkígbà tí ẹnìkan bá wá wò mí, wọn ń sọ̀rọ̀ ẹ̀tàn, nígbà tí àyà rẹ̀ bá kó ẹ̀ṣẹ̀ jọ sí ara rẹ̀; nígbà tí ó bá jáde lọ yóò sì máa tàn án kálẹ̀.
Ug kong siya moanhi sa pagpakigkita kanako, siya magasulti ug bakak; Ang iyang kasingkasing nagatigum ug kasal-anan alang sa iyang kaugalingon: Sa diha nga mopanaw siya sa halayong dapit, siya magasulti niana.
7 Àwọn ọ̀tá mi gbìmọ̀ papọ̀ nípa mi; èmi ni wọ́n ń gbìmọ̀ ibi sí,
Ang tanan nga nanagdumot kanako, nanaglibak batok kanako sa tingub; Batok kanako nanaglalang (sila) alang sa akong kadautan.
8 wọ́n wí pé, “Ohun búburú ni ó dì mọ́ ọn ṣinṣin àti ní ibi tí ó dùbúlẹ̀ sí, kì yóò dìde mọ́.”
Ang usa ka mangil-ad nga sakit, matud nila, motakud kaniya; Ug karon nga siya nagahigda na, dili na siya makabalik sa pagbangon.
9 Pàápàá, ọ̀rẹ́ mi tímọ́tímọ́, ẹni tí mo gbẹ́kẹ̀lé, ẹni tí ó ń jẹ nínú oúnjẹ mi, tí gbé gìgísẹ̀ rẹ̀ sókè sí mi.
Oo, ang akong suod nga higala, nga gisaligan ko, Nga nakakaon sa akong tinapay, Nag-alsa sa iyang tikod batok kanako.
10 Ṣùgbọ́n ìwọ Olúwa, ṣàánú fún mi; gbé mi sókè, kí ń ba lè san fún wọn.
Apan ikaw, Oh Jehova, malooy ka kanako, ug patindoga ako, Aron igabayad ko kanila ang balus.
11 Èmi mọ̀ pé inú rẹ̀ dùn sí mi, nítorí ọ̀tá mi kò borí mi.
Pinaagi niini maila ko nga ikaw nahamuot kanako, Tungod kay ang akong kaaway dili makadaug kanako.
12 Bí ó ṣe tèmi ni ìwọ dì mímú nínú ìwà òtítọ́ mi ìwọ sì gbé mi kalẹ̀ níwájú rẹ títí láé.
Ug mahitungod kanako, ikaw nagasagang sa akong pagkatarung, Ug nagapapuyo kanako sa atubangan sa imong nawong sa walay katapusan.
13 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, láé àti láéláé.
Bulahan si Jehova, ang Dios sa Israel, Gikan sa walay katapusan ngadto sa walay katapusan. Hinaut unta, ug Hinaut unta.

< Psalms 41 >