< Psalms 40 >

1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Saamu. Mo fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ dúró de Olúwa; ó sì dẹtí sí mi, ó sì gbọ́ ẹkún mi.
Na da Hina Gode Ea fidima: ne gebewane ouesalu. Amalalu E da na dini iabe amo nabi.
2 Ó fà mí yọ gòkè láti inú ihò ìparun, láti inú ẹrẹ̀ pọ̀tọ̀pọ́tọ̀, ó sì fi ẹsẹ̀ mi lé orí àpáta, ó sì jẹ́ kí ìgbésẹ̀ mi wà láìfòyà.
Na da fafu wayabo amoga bogoma: ne bosona dalu. Be Hina Gode da na hiougia gadoi. E da na gaga: musa: , magufu da: iya asunasi.
3 Ó fi orin tuntun sí mi lẹ́nu, àní orin ìyìn sí Ọlọ́run wa. Ọ̀pọ̀ yóò rí i wọn yóò sì bẹ̀rù, wọn yóò sì gbẹ́kẹ̀lé Olúwa.
E da nama gesami gaheabolo hea: ma: ne olelei. Amo gesami da Godema nodone hea: su gesami. Dunu bagohame da amoba: le dawa: digili ilia da Hina Godema dafawaneyale dawa: mu.
4 Ayọ̀ ni fún àwọn wọ̀n-ọn-nì tí ó fi Olúwa ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé wọn tí wọn kò sì yípadà sí agbéraga, tàbí àwọn tí ó yapa lọ sí ọ̀dọ̀ ọlọ́run mìíràn.
Nowa dunu ilia da Hina Godema dafawaneyale dawa: sa, amola ogogole loboga hamoi ‘gode’ ilima hame fa: no bobogesa, amola dunu ilia da ogogosu ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadosea ilima hame gilisisa, amo dunu ilia da hahawane bagade gala.
5 Olúwa Ọlọ́run mi, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn iṣẹ́ ìyanu tí ìwọ ti ṣe. Àwọn ohun tí ìwọ ti ṣètò sílẹ̀ fún wa; ni ẹnikẹ́ni kò le kà wọ́n fún ọ lẹ́sẹẹsẹ, tí èmi yóò sì sọ̀rọ̀ wọn, wọ́n ju ohun tí ènìyàn le è kà lọ.
Ninia Hina Gode! Di da ninima liligi bagohame hamoi dagoi. Dunu afae Di agoai da hamedafa gala. Di da nini fidima: ne, ilegesu ida: iwane bagohame hamoi dagoi. Na da amo ilegesu huluane olelemu da hamedei. Ili idimu da hamedei.
6 Ẹbọ àti ẹran ẹbọ ni ìwọ kò fẹ́, ìwọ ti ṣí mi ní etí. Ọrẹ ẹbọ sísun àti ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ ni ìwọ kò béèrè.
Di da gobele salasu amola Godema iasu amo hame hanai. Di da ohe oloda da: iya gogo gobele salasu amo hame adole ba: sa. Amola Di da wadela: i hou fadegale fasima: ne, gobele salasu hou amo hame hanasa. Be amo mae dawa: le, Di da nama nabasu hou hamoma: ne, ge hahamonesi.
7 Nígbà náà ni mo wí pé, “Èmi nìyí; nínú ìwé kíká ni a kọ ọ nípa tèmi wí pé.
Amaiba: le, na da Dima amane adole i, “Na da goea! Dia nama hamoma: ne sia: i da Sema Buga amo ganodini dedei diala.
8 Mo ní inú dídùn láti ṣe ìfẹ́ ẹ̀ rẹ, ìwọ Ọlọ́run mi, òfin rẹ̀ ń bẹ ní àyà mi.”
Na da Dia hanai amo hamomusa: bagadewane hanai galebe. Dia malasu da na dogo ganodini diala.”
9 Èmi ti sọ ìròyìn ayọ̀ ti ìgbàlà láàrín àwùjọ ńlá; wò ó, èmi kò pa ètè mi mọ́, gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti mọ̀, ìwọ Olúwa.
Hina Gode! Dia dunu huluane gilisi amo ganodini na da sia: ida: iwane gala ilima olelei. Amo sia: da ‘Di da nini gaga: lala’. Di dawa: ! Amo sia: olelebe, na da hamedafa yolesimu.
10 Èmi kò fi ìrànlọ́wọ́ ìgbàlà sin ní àyà mi; èmí ti sọ̀rọ̀ nípa òtítọ́ àti ìgbàlà rẹ. Èmi kò sì pa ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti òtítọ́ rẹ̀ mọ́ kúrò láàrín àwọn ìjọ ńlá.
Na da Dia gaga: su hou olelebe amo nisu hame gei dialu. Na da eso huluane Dia mae fisili fidisu hou olelelalu. Dia dunu huluane gilisi amo ganodini na da mae ouiya: le, Dia mae fisili asigidafa hou olelelalu.
11 Ìwọ má ṣe, fa àánú rẹ tí ó rọ́nú sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ mi Olúwa; jẹ́ kí ìṣeun ìfẹ́ rẹ àti òtítọ́ rẹ kí ó máa pa mi mọ́ títí ayérayé.
Hina Gode! Na dawa: ! Dia da nama gogolema: ne olofosu asigidafa hou hamedafa dagolesimu. Dia da nama mae fisili asigidafa hou hamonanebeba: le na da gaga: i dagoi ba: lalumu.
12 Nítorí pé àìníye ibi ni ó yí mi káàkiri, ẹ̀ṣẹ̀ mi sì dì mọ́ mi, títí tí èmi kò fi ríran mọ́; wọ́n pọ̀ ju irun orí mi lọ, àti wí pé àyà mí ti kùnà.
Na da bidi hamosu bagohame amoga sisiga: le disi. Amo bidi hamosu da idimu gogolei ba: sa. Na wadela: i hou ilia se dabe iasu da nama doaga: i dagoi. Na da si dofoi agoai galebe. Na wadela: i hou idi da nina: dialuma hinabo idi baligisa. Amaiba: le, na da bagadewane beda: i.
13 Jẹ́ kí ó wù ọ́, ìwọ Olúwa, láti gbà mí là; Olúwa, yára láti ràn mí lọ́wọ́.
Hina Gode! Na gaga: ma! Wahadafa, na fidima!
14 Gbogbo àwọn wọ̀n-ọn-nì ni kí ojú kí ó tì kí wọn kí ó sì dààmú; àwọn tí ń wá ọkàn mi láti parun jẹ́ kí a lé wọn padà sẹ́yìn kí a sì dójútì wọ́n, àwọn tí ń wá ìpalára mi.
Amo dunu na fane legemusa: manebe da hasalasili amola ededenanesima: ma! Amola dunu amo da na bidi hamosu ba: beba: le hahawane gala, ilia da ogobele gogosiasu ba: ma: ma!
15 Jẹ́ kí àwọn tí ó wí fún mi pé, “Háà! Háà!” ó di ẹni à fi ọwọ́ rọ́ sẹ́yìn nítorí ìtìjú wọn.
Dunu amo da nama lasogole oufesega: sa, amo hasalasima! Amasea, ilia da bagade beda: mu.
16 Jẹ́ kí gbogbo àwọn tí ń wá ọ kí ó máa yọ̀ kí inú wọn sì máa dùn sí ọ; kí gbogbo àwọn tí ó sì fẹ́ ìgbàlà rẹ kí o máa wí nígbà gbogbo pé, “Gbígbéga ni Olúwa!”
Dunu huluane da Dima masea, ilia da nodone hahawane ba: mu da defea. Dunu huluane amo da Dia gaga: su lai dagoiba: le Dima nodosa ilia da eso huluane, “Gode da baligili bagadedafa,” sia: mu da defea.
17 Bí ó ṣe ti èmi ni, tálákà àti aláìní ni èmi, ṣùgbọ́n Olúwa ń ṣe ìrántí mi. Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ mi àti ìgbàlà mi; má ṣe jẹ́ kí ó pẹ́, ìwọ Ọlọ́run mi.
Hina Gode! Na da gasa hamedeidafa amola hame gagui gala! Be Di da na hame gogolei. Di da na Gaga: su amola na Gode gala! Nama hedolo fidila misa!

< Psalms 40 >