< Psalms 4 >

1 Fún adarí orin. Pẹ̀lú ohun èlò orin olókùn. Saamu ti Dafidi. Dá mi lóhùn nígbà tí mo bá pè ọ́, ìwọ Ọlọ́run òdodo mi. Fún mi ní ìdáǹdè nínú ìpọ́njú mi; ṣàánú fún mi, kí o sì gbọ́ àdúrà mi.
För sångmästaren, med strängaspel; en psalm av David.
2 Báwo ni yóò ṣe pẹ́ tó, ẹ̀yin ọmọ ènìyàn, tí ẹ ó ṣe sọ ògo mi di ìtìjú? Báwo ni yóò ṣe pẹ́ tó, tí ẹ̀yin yóò ṣe fẹ́ràn ìtànjẹ àti tí ẹ̀yin yóò fi máa wá ọlọ́run èké?
När jag ropar, så svara mig, du min rättfärdighets Gud, du som i trångmål skaffar mig rum; var mig nådig och hör min bön.
3 Ṣùgbọ́n kí ẹ mọ̀ pé, Olúwa ti ya ẹni olódodo sọ́tọ̀ fún ara rẹ̀; Olúwa yóò gbọ́ nígbà tí mo bá pè é.
I herrar, huru länge skall min ära vara vänd i smälek, huru länge skolen I älska fåfänglighet och fara efter lögn? (Sela)
4 Ẹ bínú ẹ má ṣe ṣẹ̀, nígbà tí ẹ bá wà lórí ibùsùn yín, ẹ bá ọkàn yín sọ̀rọ̀, kí ó sì dákẹ́ jẹ́.
Besinnen dock att HERREN har utvalt åt sig den fromme; HERREN hör, när jag ropar till honom.
5 Ẹ rú ẹbọ òdodo kí ẹ sì gbẹ́kẹ̀lé Olúwa.
Vredgens, men synden icke; eftersinnen i edra hjärtan, på edra läger, och varen stilla. (Sela)
6 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ló ń béèrè pé, “Ta ni yóò ṣe rere fún wa?” Olúwa, jẹ́ kí ojú rẹ mọ́lẹ̀ sí wa lára,
Offren rätta offer, och förtrösten på HERREN.
7 Ìwọ ti fi ayọ̀ púpọ̀ kún ọkàn mi ju ìgbà tí hóró irúgbìn àti wáìnì tuntun wọ́n pọ̀ fún mi lọ.
Många säga: »Vem skall låta oss se det gott är?» Upplyft du över oss ditt ansiktes ljus, o HERRE.
8 Èmi yóò dùbúlẹ̀, èmi ó sì sùn ní àlàáfíà, nítorí ìwọ nìkan, Olúwa, ni o mú mi gbé láìléwu.
Du giver mig glädje i hjärtat, större än andras, när de få säd och vin i myckenhet. I frid vill jag lägga mig ned, och i frid skall jag somna in, ty du, HERRE, låter mig bo avskild och i trygghet.

< Psalms 4 >