< Psalms 37 >

1 Ti Dafidi. Má ṣe ìkanra nítorí àwọn olùṣe búburú, kí ìwọ má sì ṣe ṣe ìlara nítorí àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀;
MAI ukiuki oe no ka poe hana hewa; Aole hoi e huahua i na mea lawehala.
2 nítorí pé wọn yóò gbẹ bí i koríko, wọn yóò sì rẹ̀ dànù bí ewéko tútù.
No ka mea, e oki koke ia lakou e like me ka mauu, A e mae hoi e like me ka laauikiai maka.
3 Gbẹ́kẹ̀lé Olúwa, kí o sì máa ṣe rere; torí pé ìwọ yóò gbé ilẹ̀ náà, kí o sì gbádùn ààbò rẹ̀.
E hilinai aku ia Iehova, a e hana i ka pono; A e noho no oe ma ka aina, a e hanai io ia'ku oe.
4 Ṣe inú dídùn sí Olúwa; òun yóò sì fún ọ ní ìfẹ́ inú rẹ̀.
E hauoli hoi oe ia Iehova, A e haawi mai no ia nou i ka makemake o kou naau:
5 Fi ọ̀nà rẹ lé Olúwa lọ́wọ́; gbẹ́kẹ̀lé pẹ̀lú, òun yóò sì ṣe é.
Hookaa aku i kou aoao ia Iehova; E hilinai aku hoi ia ia. a nana no hoi e hana.
6 Yóò sì mú kí òdodo rẹ̀ jáde bí ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀, àti ìdájọ́ rẹ̀ bí ọ̀sán gangan.
A e hoopuka mai hoi oia i kou pono e like me ka malamalama, A me kou hooponoponoia e like me ka la ku pono.
7 Ìwọ dákẹ́ jẹ́ẹ́ níwájú Olúwa, kí o sì fi sùúrù dúró dè é; má ṣe ṣe ìkanra nítorí àwọn tí ń rí rere ní ọ̀nà wọn, nítorí ọkùnrin náà ti mú èrò búburú ṣẹ.
E noho malie ia Iehova, a e kali ahonui ia ia; Mai noho a ukiuki no ke kanaka e pookeokeo ana i kona aoao iho, No ke kanaka e hana ana ma na manao hewa.
8 Fàsẹ́yìn nínú inúbíbí, kí o sì kọ ìkáàánú sílẹ̀, má ṣe ṣe ìkanra, kí ó má ba à ṣé búburú pẹ̀lú.
E waiho i ka huhu, e haalele hoi i ka inaina; Mai nauki iki e hana hewa ai.
9 Nítorí tí á ó gé àwọn olùṣe búburú kúrò, ṣùgbọ́n àwọn tí ó bá dúró de Olúwa àwọn ni yóò jogún ilẹ̀ náà.
No ka mea, e okiia'ku ka poe hana hewa; Aka, o ka poe manaolana ia Iehova, e loaa ia lakou ka honua.
10 Síbẹ̀ nígbà díẹ̀ sí i, àwọn ènìyàn búburú kì yóò sí mọ̀; nítòótọ́ ìwọ yóò fi ara balẹ̀ wo ipò rẹ̀, wọn kì yóò sí níbẹ̀.
A liuliu iki aku, aole ka mea lawehala; Oiaio, e hoomanao ikaika oe i kona wahi, aole hoi ia.
11 Ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́kàn tútù ni yóò jogún ilẹ̀ náà, wọn yóò sì máa ṣe inú dídùn nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àlàáfíà.
Aka, e loaa ka honua i ka poe hoohaahaa; He hauoli lakou i ka pomaikai nui wale.
12 Ènìyàn búburú di rìkíṣí sí olóòtítọ́, wọ́n sì pa eyín wọn keke sí wọn;
Kukakuka ku e ka mea hewa i ka mea pono, A nau iho la me kona mau niho ia ia.
13 ṣùgbọ́n Olúwa rẹ́rìn-ín sí àwọn ènìyàn búburú, nítorí tí ó rí wí pé ọjọ́ wọn ń bọ̀.
E akaaka mai no nae ka Haku ia ia; No ka mea, ua ike oia i ke kokoke ana mai o kona la.
14 Ènìyàn búburú fa idà yọ, wọ́n sì tẹ àwọn ọrun wọn, láti sọ tálákà àti aláìní kalẹ̀, láti pa àwọn tí ó dúró ṣinṣin.
Ua unuhi ae la ka poe hewa i ka pahikaua, Ua lena hoi i ka lakou kakaka, E hoolilo i ka poe ilihune a me ka poe haahaa, A e hoomake hoi i ka poe e hele pono ana.
15 Idà wọn yóò wọ àyà wọn lọ, àti wí pé ọrun wọn yóò sì ṣẹ́.
E komo no ko lakou pahikaua i ko lakou naau iho; A e uhakiia ka lakou kakaka.
16 Ohun díẹ̀ tí olódodo ní, sàn ju ọ̀pọ̀ ọrọ̀ ènìyàn búburú;
Ua oi aku ka waiwai uuku o ke kanaka pono Mamna o ka waiwai nui o ka poe hewa he nui.
17 nítorí pé a óò ṣẹ́ ọwọ́ àwọn ènìyàn búburú, ṣùgbọ́n Olúwa gbé olódodo sókè.
No ka mea, e uhakiia na lima o ka poe hewa; Aka, e hookupaa iho o Iehova i ka poe pono.
18 Olúwa mọ àwọn ọjọ́ àwọn tó dúró ṣinṣin, àti wí pé ilẹ̀ ìní wọn yóò wà títí ayérayé.
Ua ike o Iehova i na la o ka poe ku pono; A e mau loa ana no hoi ko lakou hooilina.
19 Ojú kì yóò tì wọ́n ní àkókò ibi, àti ní ọjọ́ ìyàn, a ó tẹ́ wọn lọ́rùn.
Aole lakou e hoka i ka manawa ino; A i ke kau wi e maona no lakou.
20 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn búburú yóò ṣègbé. Àwọn ọ̀tá Olúwa yóò dàbí ẹwà oko tútù; wọn fò lọ; bi èéfín ni wọn yóò fò lọ kúrò.
Aka, e make no ka poe hewa, A e like auanei oa enemi o Iehova me'ka momona o na keikihipa; E pau lakou i ke ahi, e lilo lakou i uahi.
21 Àwọn ènìyàn búburú yá, wọn kò sì san án padà, ṣùgbọ́n àwọn olódodo a máa ṣàánú, a sì máa fi fún ni;
Ua noi e lawe iki ka mea hewa i ka hai. aole nae i hoihoi mai: Aka e lokomaikai aka ka mea pono, a haawi wale aku no.
22 nítorí àwọn tí Olúwa bá bùkún ni yóò jogún ilẹ̀ náà, àwọn tí ó fi bú ni a ó gé kúrò.
Nolaila o ka poe hoomaikaiia e ia e loaa ia lakou ka honua; Aka, o ka poe i hoinoia e ia e okiia lakou.
23 Ìlànà ìgbésẹ̀ ènìyàn rere wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá, o sì ṣe inú dídùn sí ọ̀nà rẹ̀;
Ua hooku pono ia e Iehova na kapuwai o ke kanaka pono; Oluolu mai no oia i kona hele ana.
24 bí ó tilẹ̀ ṣubú a kì yóò ta á nù pátápátá, nítorí tí Olúwa di ọwọ́ rẹ̀ mú.
Ina e hina ia aole ia e hoohiolo loa ia: No ka mea, ua hookupaa o Iehova ia ia me kona lima.
25 Èmi ti wà ni èwe, báyìí èmi sì dàgbà; síbẹ̀ èmi kò ì tí ì ri kí a kọ olódodo sílẹ̀, tàbí kí irú-ọmọ rẹ̀ máa ṣagbe oúnjẹ.
Opiopio aku la au, a ua elemakule ae nei, Aole hoi au i ike i ka mea pono i haaleleia, Aole hoi i kana hua e makilo berena ana.
26 Aláàánú ni òun nígbà gbogbo a máa yá ni; a sì máa bùsi i fún ni.
He aloha mau kona, a ua haawi aka no; Pomaikai no hoi kana hua.
27 Lọ kúrò nínú ibi, kí o sì máa ṣe rere; nígbà náà ni ìwọ yóò gbé ní ilẹ̀ náà títí láéláé.
E haalele i ka hewa, a e hana i ka pono; A e noho mau loa aku.
28 Nítorí pé Olúwa fẹ́ràn ìdájọ́ òtítọ́, kò sì kọ àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ sílẹ̀. Àwọn olódodo ni a ó pamọ́ títí ayérayé, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ènìyàn búburú ni a ó ké kúrò.
No ka mea, ua makemake no Iehova i ka hoopono ana: Aole ia i haalele i kona poe haipule; E hoomalu mau loa ia hoi lakou; Aka, e okiia ka hua a ka poe hewa.
29 Olódodo ni yóò jogún ilẹ̀ náà, yóò sì máa gbé ibẹ̀ títí ayérayé.
E loaa ka aina i ka poe pono, A e noho mau lakou ilaila.
30 Ẹnu olódodo sọ̀rọ̀ ọgbọ́n, ahọ́n rẹ̀ a sì máa sọ̀rọ̀ ìdájọ́.
Ua olelo ka waha o ka mea pono ma ka naauao; A ua kamailio kona alelo ma ka hoopono ana.
31 Òfin Ọlọ́run rẹ̀ ń bẹ ní àyà wọn; àwọn ìgbésẹ̀ rẹ̀ kì yóò yẹ̀.
Maloko o kona naau ke kanawai o kona Akua; Aole kapuwai ona e kapeke ai.
32 Ènìyàn búburú ń ṣọ́ olódodo, Ó sì ń wá ọ̀nà láti pa á.
Kiai ka mea hewa i ka mea pono, A imi hoi ia e hoomake ia ia.
33 Olúwa kì yóò fi lé e lọ́wọ́ kì yóò sì dá a lẹ́bi, nígbà tí a bá ń ṣe ìdájọ́ rẹ̀.
Aole e waiho mai o Iehova ia ia iloko o kona lima, Aole hoi e hoahewa ia ia i kona wa e hookolokoloia'i.
34 Dúró de Olúwa, kí o sì máa pa ọ̀nà rẹ̀ mọ́. Yóò sì gbé ọ lékè láti jogún ilẹ̀ náà; nígbà tí a bá gé àwọn ènìyàn búburú kúrò ìwọ yóò ri.
E hilinai aku ia Iehova, a e malama i kona aoao: A e hookiekie oia ia oe e komo i ka aina; Aia okiia ka poe hewa, e ike ako no oe ia.
35 Èmi ti rí ènìyàn búburú tí ń hu ìwà ìkà, ó sì fi ara rẹ̀ gbilẹ̀ bí igi tútù ńlá,
Ua ike aku au i ke kanaka hewa e weliweli ai, E hoopalahalaha ana ia ia iho e like me ka laau uliuli i kona wahi iho.
36 ṣùgbọ́n ní ìṣẹ́jú kan sí i ó kọjá lọ, sì kíyèsi, kò sì sí mọ́; bi ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé mo wá a kiri, ṣùgbọ́n a kò le è ri.
Aka, ua hala aku la ia aia hoi, aole iho la ia; Oiaio, imi aku la au ia ia, aole hoi ia i loaa.
37 Máa kíyèsi ẹni pípé, kí o sì wo ẹni tó dúró ṣinṣin; nítorí àlàáfíà ni òpin ọkùnrin náà.
E noonoo i ke kanaka hemolele, E nana hoi i ka mea kupono: No ka mea, o ka hope o ua kanaka la, he pomaikai no ia.
38 Ṣùgbọ́n àwọn olùrékọjá ni a ó parun papọ̀; ìran àwọn ènìyàn búburú ni a ó gé kúrò.
Aka, e luku pu ia ka poe lawehala; A o ka hope o ka poe hewa, e okiia no ia.
39 Ìgbàlà àwọn onídùúró ṣinṣin wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa; òun ni ààbò wọn ní ìgbà ìpọ́njú
Aka, no Iehova mai ke ola o ka poe pono: Oia ko lakou ikaika i ka wa popilikia.
40 Olúwa yóò ràn wọ́n lọ́wọ́ yóò sì gbà wọ́n; yóò gbà wọ́n lọ́wọ́ ènìyàn búburú, yóò sì gbà wọ́n là, nítorí tí wọ́n gbẹ́kẹ̀lé e.
A e kokua mai o Iehova ia lakou, a e hoakea mai ia lakou, E hoopakele oia ia lakou i ka poe hewa, A e hoola ia lakou. no ko lakou hilinai ana ia ia.

< Psalms 37 >