< Psalms 35 >

1 Ti Dafidi. Olúwa, gbógun ti àwọn tí ń gbóguntì mí; kí o sì kọ ojú ìjà sí àwọn tí ó ń bá mi í jà!
E HAKAKA, e Iehova, me na mea i hakaka me au: E paio oe me ka poe i paio mai ia'u,
2 Di asà àti àpáta mú, kí o sì dìde fún ìrànlọ́wọ́ mi!
E lalau i ka palekaua a me ka uhikino, A e ku mai oe iluna i kokua no'u
3 Fa idà àti ọ̀kọ̀ yọ kí o sì dojúkọ àwọn tí ń lé mi. Sọ fún ọkàn mi pé, “Èmi ni ìgbàlà rẹ.”
Unuhi ae hoi oe i ka ihe a e keakea i ka poe alualu hewa mai ia'u: E olelo mai i kuu uhane, Owau no kou ola.
4 Kí wọn kí ó dààmú, kí a sì ti àwọn tí ń lépa ọkàn mi lójú; kí a sì mú wọn padà, kí a sì dààmú àwọn tí ń gbèrò ìpalára mi.
E hoka a e hoohilahilaia ka poe i kii mai i ko'u uhane; E hoohuliia'ku lakou i hope, a e hoohokaia hoi na mea i kukakuka i ka ino no'u.
5 Jẹ́ kí wọn dàbí ìyàngbò níwájú afẹ́fẹ́, kí angẹli Olúwa kí ó máa lé wọn kiri.
E like lakou me ka opala imua o ka makani, A e alualu ka anela o Iehova.
6 Jẹ́ kí ọ̀nà wọn kí ó ṣókùnkùn, kí ó sì máa yọ́, kí angẹli Olúwa kí ó máa lépa wọn!
A pouli mai, a pahee hoi ko lakou alanui, A e alualu hoi ka anela a Iehova ia lakou.
7 Nítorí pé, ní àìnídìí ni wọ́n dẹ àwọ̀n wọn sílẹ̀ fún mi, ní àìnídìí ni wọ́n wa kòtò sílẹ̀ fún ọkàn mi.
No ka mea, i ka hala ole, huua lakou i ka lakou upena no'u, Iloko o ka lua a lakou i eli ai no kuu uhane, i ka hala ole.
8 Kí ìparun kí ó wá sí orí rẹ̀ ní òjijì. Àwọ̀n rẹ̀ tí ó dẹ, kí ó mú òun tìkára rẹ̀; kí wọn ṣubú sínú kòtò sí ìparun ara rẹ̀.
E kau mai ka make ike ole ia maluna ona; A e hoohei ia ia iho kana upena i huna ai; Iloko o ua make la e haule iho ai oia.
9 Nígbà náà ni ọkàn mi yóò yọ̀ nínú Olúwa, àní, yóò sì máa yọ̀ nínú ìgbàlà rẹ̀.
E hauoli ko'u uhane ia Iehova; E olioli no hoi i kona hoola ana.
10 Gbogbo egungun mi yóò wí pé, “Ta ni ó dàbí ì ìwọ Olúwa? O gba tálákà lọ́wọ́ àwọn tí ó lágbára jù ú lọ, tálákà àti aláìní lọ́wọ́ ẹni tí ń fi ṣe ìkógun?”
E olelo aku no hoi ka'u mau iwi a pau, E Iehova, owai la ka mea like me oe? Ka mea i hoopakele i ka mea haahaa i ka mea i oi ka ikaika i kona, Oia hoi, o ka mea ilihune me ka nele i ka mea hao wale ia ia?
11 Àwọn ẹlẹ́rìí èké dìde; wọ́n ń bi mi ní ohun tí èmi kò mọ̀.
Ua ku iluna na hoike wahahee; Ua hookolokolo mai lakou ia'u ma na mea a'u i ike ole ai.
12 Wọ́n fi búburú san ìre fún mi; láti sọ ọkàn mi di òfo.
Ua uku mai lakou ia'u me ka hewa no ka pono, I haalele loa ia ko'u uhane.
13 Ṣùgbọ́n bí ó ṣe ti èmi ni, nígbà tí wọn ń ṣe àìsàn, mo wọ aṣọ ọ̀fọ̀; mo fi àwẹ̀ pọ́n ara mi lójú. Mo gba àdúrà pẹ̀lú ìtẹríba ní oókan àyà mi;
Aka, owau nei la, i ko lakou mai ana, O ke kapa ino ka'u i aahu ai: A hookaumaha au i kuu uhane me ka hookeai, A ua hoi mai ka'u pule iloko o kuu poli iho.
14 èmí ń lọ kiri bí ẹni ń ṣọ̀fọ̀ bí i ẹni wí pé fún ọ̀rẹ́ tàbí ẹ̀gbọ́n mi ni. Èmí tẹríba nínú ìbànújẹ́ bí ẹni tí ń ṣọ̀fọ̀ ìyà rẹ̀.
Ua hele au me he mea la o ko'u hoaaloha, a o ko'u hoahanau paha ia: Ua kulou iho au me ke kaumaha, E like me ka mea kanikau no kona makuwahine.
15 Ṣùgbọ́n nínú ìkọ̀sẹ̀ mi wọ́n sì yọ̀, wọ́n sì kó ara wọn jọ; wọ́n kó ara wọn jọ sí mi; àní àwọn tí èmi kò mọ̀. Wọ́n fà mí ya wọ́n kò sì dákẹ́.
Aka, i kuu oopa ana, olioli lakou, a akoakoa hoi, Oia hoi ua akoakoa ku e ia ia'u ka poe aki, aole hoi au i ike, Ua haehae mai lakou ia'u aole i noho malie.
16 Bí àwọn àgàbàgebè tí ń ṣe ẹlẹ́yà ní àpèjẹ wọ́n pa eyín wọn keke sí mi.
Iwaena o na aia hoakaaka ma na ahaaina, Nau mai lakou i ko lakou mau niho ia'u.
17 Yóò ti pẹ́ tó Olúwa, tí ìwọ yóò máa wò wọ́n lọ? Yọ mí kúrò nínú ìparun wọn, àní ẹ̀mí ì mi kúrò lọ́wọ́ kìnnìún.
E ka Haku, pehea ka loihi o kou nana ana mai? E hoopakele i kuu uhane i ko lakou luku ana, A i ko'u makamae i na liona.
18 Nígbà náà ni èmi yóò ṣọpẹ́ fún Ọ nínú àjọ ńlá; èmi yóò máa yìn Ọ́ ní àwùjọ ọ̀pọ̀ ènìyàn.
E hoomaikai aku au ia oe iloko o ke anaina nui; E hoolea aku au ia oe iwaena o na kanaka lehulehu.
19 Má ṣe jẹ́ kí àwọn ọ̀tá mi kí ó yọ̀ lórí ì mi; bẹ́ẹ̀ ni kí o má ṣe àwọn tí ó kórìíra mi ní àìnídìí máa ṣẹ́jú sí mi.
Mai noho a hauoli hewa mai ko'u mau enemi maluna o'u: A imo me ka maka ka poe inaina wale mai ia'u.
20 Nítorí pé wọn kò sọ ọ̀rọ̀ àlàáfíà, ṣùgbọ́n wọ́n lóyún ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn sí àwọn ènìyàn dídákẹ́ ilẹ̀ náà.
No ka mea, aole lakou i olelo ma ke kuikahi; Ua kukakuka lakou i na mea hoopunipuni ku e i na mea noho malie ma ka aina.
21 Wọ́n ya ẹnu wọn gbòòrò sí mi; wọ́n wí pé, “Háà! Háà! Ojú wa sì ti rí i.”
Oiaio, ua hoohamama loa lakou i ko lakou waha ia'u; I iho la lakou, Aia la! aia la! ua ike ko makou maka ia.
22 Ìwọ́ ti rí i Olúwa; má ṣe dákẹ́! Olúwa má ṣe jìnnà sí mi!
Oia kau i ike mai ai, e Iehova, mai hakanu oe, E ka Haku, mai noho a mamao aku ia'u.
23 Dìde! ru ara rẹ̀ sókè fún ààbò mi, àti sí ọ̀ràn mi, Ọlọ́run mi àti Olúwa mi!
E paipai ia oe iho, e ala'e hoi e hoopono ia'u; Ma kuu mea e hakaka ai, e kuu Akua, e kuu Haku hoi.
24 Ṣe ìdájọ́ mi, Olúwa Ọlọ́run mi, gẹ́gẹ́ bí òdodo rẹ, kí o má sì ṣe jẹ́ kí wọn kí ó yọ̀ lórí mi!
E hoopono mai ia'u, e Iehova kuu Akua, mamuli o kou pono; Mai noho a hauoli lakou maluna o'u.
25 Má ṣe jẹ́ kí wọn wí nínú ara wọn pé, “Háà! A ti rí ohun tí ọkàn wa ń fẹ́!” Má ṣe jẹ́ kí wọn kí ó wí pé, “A ti gbé e mì.”
Mai noho a olelo lakou iloko o ko lakou naau, Aia la! O ko makou makemake no ia: Mai noho a olelo lakou, Ua ale kakou ia ia.
26 Kí ojú kí ó tì wọ́n, kí wọn kí ó sì dààmú pọ̀, àní àwọn tí ń yọ̀ sí ìyọnu mi kí a fi ìtìjú àti àbùkù wọ̀ wọ́n ní aṣọ tí ń gbéraga sí mi.
E hoka a e hoohilahila pu ia no hoi ka poe hauoli i ko'u poino; E hoaahuia me ka hilahila a me ka hoinoia ka poe haanui ku e mai ia'u.
27 Jẹ́ kí àwọn tí ó fẹ́ ìdáláre mi fò fún ayọ̀ àti ìdùnnú; kí wọn máa sọ ọ́ títí lọ, “Pé gbígbéga ni Olúwa, sí àlàáfíà ìránṣẹ́ rẹ̀.”
E hooho i ka olioli a e hauoli hoi ka poe kokua i kuu pono; A e olelo mau lakou, E mahaloia'ku o Iehova, Ka mea i oluolu i ka pomaikai o kana kauwa nei.
28 Nígbà náà ni ahọ́n mi yóò máa sọ̀rọ̀ òdodo rẹ, àti ìyìn rẹ ní gbogbo ọjọ́.
A e hai aku kuu alelo i kou hoopono ana, A i ka hoolea nou a po ka la.

< Psalms 35 >