< Psalms 33 >

1 Ẹ yọ̀ nínú Olúwa, ẹ̀yin olódodo; ìyìn si yẹ fún ẹni dídúró ṣinṣin.
Molole hamosu dunu, dilia! Hina Gode Ea hamoi dawa: beba: le, hahawaneba: le wele sia: ma! Ema nabasu dunu! Ema nodone sia: ma!
2 Ẹ yin Olúwa pẹ̀lú dùùrù; ẹ máa fi ohun èlò olókùn mẹ́wàá kọrin sí i.
Hina Godema nodoma: ne, baidama amola ilibu amola sani baidama huluane dududu sa: ima.
3 Ẹ kọ orin tuntun sí i; ẹ máa fi ọgbọọgbọ́n lu ohun èlò orin sí i, pẹ̀lú ariwo.
Ema gaheabolo gesami hea: ma. Dawa: iwane sani baidama duma amola hahawaneba: le, wele sia: ma.
4 Nítorí pé ọ̀rọ̀ Olúwa dúró ṣinṣin, gbogbo iṣẹ́ rẹ̀ ni à ń ṣe nínú òtítọ́.
Hina Gode Ea sia: i liligi huluane da dafawanedafa. Amola ea hamobe huluane da mugulumu hamedei ba: sa.
5 Ó fẹ́ òtítọ́ àti ìdájọ́; ilé ayé kún fún ìdúró ṣinṣin àti àánú Olúwa.
Hina Gode da moloidafa hou amoma dogolegesa. Osobo bagade da Ea asigidafa hou amoga nabai gala.
6 Nípasẹ̀ ọ̀rọ̀ Olúwa ni a ṣe dá àwọn ọ̀run, àti gbogbo àwọn ẹgbẹ́ ogun wọn nípa ìmísí ẹnu rẹ̀.
Hina Gode da Ea sia: ga fawane mu amola eso amola oubi amola gasumuni huluane hahamoi dagoi.
7 Ó kó àwọn omi òkun jọ gẹ́gẹ́ bí èyí tí ó wà nínú ìgò; ó sì fi ibú ṣe ilé ìṣúra gbogbo.
E da hano wayabo huluane gagadolesi. E da fedege agoane, hano wayabo bagade lugudu huluane gagadole legei.
8 Jẹ́ kí gbogbo ayé kí ó bẹ̀rù Olúwa: jẹ́ kí gbogbo àwọn olùgbé ayé kí ó wà nínú ìbẹ̀rù rẹ̀.
Osobo bagade dunu huluane! Hina Godema beda: ma! Ema nodone sia: ma!
9 Nítorí tí ó sọ̀rọ̀, ó sì ti rí bẹ́ẹ̀; ó pàṣẹ ó sì dúró ṣinṣin.
Ea sia: beba: le fawane, E da osobo bagade hahamoi dagoi. Liligi huluanedafa da Ea sia: beba: le fawane doaga: i.
10 Olúwa ti mú ìmọ̀ràn àwọn orílẹ̀-èdè wá sí asán; ó sì mú àrékérekè àwọn ènìyàn di ṣíṣákì í.
Hina Gode da fifi asi gala ilia ilegesu amo hedofasa. E da ilia ilegei mae hamoma: ne, logo ga: sa.
11 Ìgbìmọ̀ Olúwa dúró títí ayérayé, àní ìrò inú rẹ̀ láti ìrandíran ni.
Be Ea ilegei da mae yolele, amanewane dialumu. Ea hanai ilegei da gebewane dialumu.
12 Ìbùkún ni fún orílẹ̀-èdè náà, Ọlọ́run ẹni tí Olúwa jẹ́ tirẹ̀, àti àwọn ènìyàn náà tí ó ti yàn ṣe ìní rẹ̀.
Fifi asi gala amo da Hina Gode da ilia Godedafa sia: sa, amo da hahawane gala. Hina Gode Ea ilegele lai dunu da hahawane bagade gala.
13 Olúwa wò láti ọ̀run wá; Ó sì rí gbogbo ìran ènìyàn.
Hina Gode da Hebene gadonini, dunu fifi asi huluane ba: le gudusa.
14 Níbi tí ó ti jókòó lórí ìtẹ́ Ó wo gbogbo àwọn olùgbé ayé
Ea ouligisu sogebi amoganini, E da osobo bagade fifi asi dialebe ilima ba: le gudusa.
15 ẹni tí ó ṣe àyà wọn bákan náà, ó sì kíyèsi ìṣe wọn.
E da ilia asigi dawa: su huluane hahamosa amola ilia hamobe huluane dawa:
16 A kò gba ọba kan là nípasẹ̀ ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọmọ-ogun; kò sì sí jagunjagun tí a gbà sílẹ̀ nípa agbára ńlá rẹ̀.
Osobo bagade hina bagade da ea gasa bagade dadi gagui wa: i, amoba: le hame hasalasa. Dadi gagui dunu da ea gasa bagadeba: le, hame hasala.
17 Ohun asán ni ẹṣin fún ìṣẹ́gun; bẹ́ẹ̀ ni kì yóò fi agbára ńlá rẹ̀ gbani sílẹ̀.
Gegesu hosi da hasalimu hamedei. Ilia da gasa bagade, be amoga gaga: su da hame ba: mu.
18 Wò ó, ojú Olúwa wà lára àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀, àti lára àwọn tí ó ní ìrètí nínú ìfẹ́ rẹ̀ tí ó dúró ṣinṣin.
Hina Gode da dunu amo da Ema nabawane fa: no bobogesa amola Ea mae fisili asigidafa hou dafawaneyale dawa: sa, amo noga: le ouligisa.
19 Láti gba ọkàn wọn kúrò lọ́wọ́ ikú àti láti pa wọ́n mọ́ láààyè lọ́wọ́ ìyàn.
Ili da mae bogoma: ne, E da ili gaga: sa. Amola ha: i esoga, ili esaloma: ne fidisa.
20 Ọkàn wa dúró de Olúwa; òun ni ìrànlọ́wọ́ wa àti asà wa.
Hina Gode da ninima hobea misunu hou amo noga: le ouligimu, ninia dafawaneyale dawa: sa. E da ninia gaga: su dunu amola ninia fidisu dunu.
21 Ọkàn wa yọ̀ nínú rẹ̀, nítorí pé, àwa gbẹ́kẹ̀lé orúkọ rẹ mímọ́.
Ninia da Ea houba: le hahawane gala. Ninia da Ea Hadigi Dio dafawaneyale dawa: sa.
22 Kí àánú rẹ, Olúwa, kí ó wà lára wa, àní gẹ́gẹ́ bí àwa ti ń ṣe ìrètí nínú rẹ.
Hina Gode! Dia mae fisili asigidafa hou da ninima dialoma: ma! Bai ninia da Diba: le, dafawane hamoma: beyale dawa: beba: le, Dima fa: no bobogesa.

< Psalms 33 >