< Psalms 32 >

1 Ti Dafidi. Maskili. Ìbùkún ni fún àwọn tí a dárí ìrékọjá wọn jì, tí a sì bo ẹ̀ṣẹ̀ wọn mọ́lẹ̀.
Thaburi ya Daudi Kũrathimwo-rĩ, nĩ ũrĩa ũrekeirwo mahĩtia make, o ũrĩa mehia make mahumbĩrĩtwo.
2 Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà ẹni tí Olúwa kò ka ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ sí i lọ́rùn àti nínú ẹ̀mí ẹni tí kò sí ẹ̀tàn.
Kũrathimwo-rĩ, nĩ mũndũ ũrĩa Jehova atatuaga mwĩhia, na ũrĩa ũtarĩ ũhinga ngoro.
3 Nígbà tí mo dákẹ́, egungun mi di gbígbó dànù nípa ìkérora mi ní gbogbo ọjọ́.
Rĩrĩa ndakirĩte ki, mahĩndĩ makwa nĩmahinyarire nĩ ũndũ wa gũcaaya gwakwa mũthenya wothe.
4 Nítorí pé ni ọ̀sán àti ní òru ọwọ́ rẹ̀ wúwo sí mi lára; agbára mi gbẹ tán gẹ́gẹ́ bí ooru ẹ̀ẹ̀rùn. (Sela)
Nĩgũkorwo guoko gwaku nĩ kwanditũhagĩra mũthenya na ũtukũ; hinya wakwa wathirire o ta ũrĩa ime rĩthiraga hĩndĩ ya riũa.
5 Èmi jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ mi sí ọ àti pé èmi kò sì fi àìṣòdodo mi pamọ́. Èmi wí pé, “Èmi yóò jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ mi fún Olúwa,” ìwọ sì dárí ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ mi jì mí. (Sela)
Hĩndĩ ĩyo ngĩkumbũrĩra mehia makwa, na ndiahithire waganu wakwa, ndoigire atĩrĩ, “Nĩngumbũra mahĩtia makwa kũrĩ Jehova,” nawe ũkĩndekera ũũru wa mehia makwa.
6 Nítorí náà jẹ́ kí gbogbo àwọn olódodo máa gbà àdúrà sí ọ ní ìgbà tí a lè rí ọ; nítòótọ́ nígbà tí ìṣàn omi ńlá bá ru sókè, wọn kì yóò lè dé ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio mũndũ wothe mwĩtigĩri Ngai nĩakũhooe rĩrĩa ũngĩoneka; ti-itherũ rĩrĩa maaĩ maingĩ marĩ hinya maambũrũrũka, matingĩmũkinyĩra.
7 Ìwọ ni ibi ìpamọ́ mi; ìwọ yóò pa mí mọ́ kúrò nínú ìyọnu; ìwọ yóò fi orin ìgbàlà yí mi ka. (Sela)
Wee nĩwe kĩĩhitho gĩakwa; nĩũkangitĩra hĩndĩ ya mathĩĩna, na ũũthiũrũrũkĩrie na nyĩmbo cia ũhonokio.
8 Èmi yóò kọ́ ọ, èmi yóò sì fi ẹsẹ̀ rẹ lé ọ̀nà tí ìwọ yóò rìn èmi yóò máa gbà ọ́ ní ìyànjú, èmi yóò sì máa fi ojú mi tọ́ ọ.
Nĩndĩrĩkũrutaga na ngakuonereria njĩra ĩrĩa wagĩrĩirwo nĩ kũgera; ndĩrĩgũtaaraga na ngũmenyagĩrĩre.
9 Má ṣe dàbí ẹṣin tàbí ìbáaka, tí kò ní òye ẹnu ẹni tí a gbọdọ̀ fi ìjánu bọ̀, kí wọn má ba à súnmọ́ ọ.
Ndũkahaane ta mbarathi kana nyũmbũ, iria itarĩ ũmenyo, iria arĩ o nginya ciĩkĩrwo matamu na mĩkwa kanua, kwaga ũguo itingĩgũkuhĩrĩria.
10 Ọ̀pọ̀ ìkáàánú ní yóò wà fún ènìyàn búburú, ṣùgbọ́n ìfẹ́ Olúwa tí ó dúró ṣinṣin ni yóò yí àwọn tí ó ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú Olúwa ká.
Andũ arĩa aaganu monaga maruo maingĩ, no mũndũ ũrĩa wĩhokaga Jehova egũtũũra arigiicĩirio nĩ wendo ũrĩa ũtathiraga.
11 Ẹ yọ̀ nínú Olúwa, kí ẹ sì ní inú dídùn, ẹ̀yìn olódodo; ẹ sì máa kọrin, gbogbo ẹ̀yìn tí àyà yín dúró ṣinṣin.
Inyuĩ arĩa athingu kenerai Jehova na mũcanjamũke; mũinĩrei, inyuothe arĩa arũngĩrĩru ngoro!

< Psalms 32 >