< Psalms 31 >

1 Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Nínú rẹ̀, Olúwa ni mo ti rí ààbò; má ṣe jẹ́ kí ojú kí ó tì mí; gbà mí nínú òdodo rẹ.
Kathutkung: Devit Oe BAWIPA, nang doeh na kâuep. Kaya hoi na awm sak hanh. Na lannae hoi na rungngang haw.
2 Tẹ́ etí rẹ sí mi, gbà mí kíákíá; jẹ́ àpáta ààbò mi, jẹ́ odi alágbára láti gbà mí.
Kai koelah na hnâpakeng nateh, karanglah na rungngang haw. Ka kâhronae lungsong hoi rungngang nahanlah ngangnae rapan lah awm haw.
3 Ìwọ pàápàá ni àpáta àti ààbò mi, nítorí orúkọ rẹ, máa ṣe olùtọ́ mi, kí o sì ṣe amọ̀nà mi.
Bangkongtetpawiteh, nang teh ka lungsong hoi ka kâhronae lah na o. Hatdawkvah, na min kecu dawk na hrawi nateh, na patue haw.
4 Yọ mí jáde kúrò nínú àwọ̀n tí wọ́n dẹ pamọ́ fún mi, nítorí ìwọ ni ìsádi mi.
Kai hanlah, arulahoi a phai awh e tamlawk dawk hoi na rasat haw. Bangkongtetpawiteh, nang teh ka thaonae doeh.
5 Ní ọwọ́ rẹ ni mo fi ẹ̀mí mi lé; ìwọ ni o ti rà mí padà, Olúwa, Ọlọ́run òtítọ́.
Oe BAWIPA, lawkkatang Cathut, na kut dawk ka muitha ka hruek.
6 Èmi ti kórìíra àwọn ẹni tí ń fiyèsí òrìṣà tí kò níye lórí; ṣùgbọ́n èmi gbẹ́kẹ̀lé Olúwa.
Cungkeihoehe meikaphawk alawkpui lah kahruengnaw hah ka hmuhma. Hatei, kai teh BAWIPA ka kâuep.
7 Èmi yóò yọ̀, inú mi yóò dùn nínú ìfẹ́ ńlá rẹ, nítorí ìwọ ti rí ìbìnújẹ́ mi ìwọ ti mọ̀ ọkàn mi nínú ìpọ́njú.
Na pahrennae lahoi, ka konawm vaiteh, ka lung pou ahawi han. Bangkongtetpawiteh, ka runae hah ouk na hmu pouh. Runae thung ka hringnae hah na panue.
8 Pẹ̀lú, ìwọ kò sì fà mi lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́ ìwọ ti fi ẹsẹ̀ mi lé ibi ààyè ńlá.
Taran kut dawk na poe laipalah, A hmuen kawnae koe ka khok hah ouk na hruek.
9 Ṣàánú fún mi, ìwọ Olúwa, nítorí mo wà nínú ìpọ́njú; ojú mi fi ìbìnújẹ́ sùn, ọkàn àti ara mi pẹ̀lú.
Oe BAWIPA, na pahren haw. Bangkongtetpawiteh, runae thungvah ka o. Ka lungmathoe lawi ka mit koung a ro toe. Bokheiyah, ka muitha hoi ka takthai totouh a ro toe.
10 Èmi fi ìbànújẹ́ lo ọjọ́ mi àti àwọn ọdún mi pẹ̀lú ìmí ẹ̀dùn; agbára mi ti kùnà nítorí òsì mi, egungun mi sì ti rún dànù.
Bangkongtetpawiteh, ka hringnae heh lungmathoenae hoi koung ka hno toe. Kum moikasawlah ka cingou. Ka payonnae ni ka thaonae a baw sak. Ka hru hai koung a hmawn toe.
11 Èmi di ẹni ẹ̀gàn láàrín àwọn ọ̀tá mi gbogbo, pẹ̀lúpẹ̀lú láàrín àwọn aládùúgbò mi, mo sì di ẹ̀rù fún àwọn ojúlùmọ̀ mi; àwọn tí ó rí mi ní òde ń yẹra fún mi.
Ka tarannaw ni pathoe hanelah doeh ka o. A lawkpui lah, ka imrinaw hanelah hoe ka o. Ka hui kahawi ni na panuet teh, lam dawk na ka hmawt e ni na yawng takhai.
12 Èmi ti di ẹni ìgbàgbé kúrò ní ọkàn gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ó ti kú; èmi sì dàbí ohun èlò tí ó ti fọ́.
Tami kadout patetlah pahnim lah ka o teh, ampaikei patetlah ka o.
13 Nítorí mo gbọ́ ọ̀rọ̀ ẹ̀gàn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìpayà tí ó yí mi ká; tí wọn gbìmọ̀ pọ̀ sí mi, wọ́n sì ṣọ̀tẹ̀ sí mi láti gba ẹ̀mí mi.
Bangkongtetpawiteh, tami moikapap ni a dei awh e ka thai. A hmuen tangkuem takinae ao. Ka hringnae la hanelah kâcai laihoi a kamkhueng awh teh, kho a khan awh.
14 Ṣùgbọ́n èmí gbẹ́kẹ̀lé ọ, ìwọ Olúwa; mo sọ wí pé, “Ìwọ ní Ọlọ́run mi.”
Hatei, Oe BAWIPA, kai ni teh nang doeh na kâuep. Ka Cathut doeh ka ti.
15 Ìgbà mi ń bẹ ní ọwọ́ rẹ; gbà mí kúrò ní ọwọ́ àwọn ọ̀tá mi àti àwọn onínúnibíni.
Kaie tuengnaw teh na kut dawk ao. Ka tarannaw kut dawk hoi, na kapahuipalamnaw kut dawk hoi, na rungngang haw.
16 Jẹ́ kí ojú rẹ kí ó tan ìmọ́lẹ̀ sí ìránṣẹ́ rẹ lára; gbà mí nínú ìfẹ́ rẹ tí ó dúró ṣinṣin.
Na san koe na mei ang naseh. Na pahrennae lahoi na rungngang lawiseh.
17 Má ṣe jẹ́ kí ojú ki ó tì mí, Olúwa; nítorí pé mo ké pè ọ́; jẹ́ kí ojú kí ó ti ènìyàn búburú; jẹ́ kí wọ́n lọ pẹ̀lú ìdààmú sí isà òkú. (Sheol h7585)
Oe BAWIPA, kaya hoi na awm sak hanh. Bangkongtetpawiteh, nang teh na kaw toe. Tamikathoutnaw teh, kaya laihoi phuen vah duem awm awh naseh. (Sheol h7585)
18 Jẹ́ kí àwọn ètè irọ́ kí ó dákẹ́ jẹ́ẹ́, pẹ̀lú ìgbéraga àti ìkẹ́gàn, wọ́n sọ̀rọ̀ àfojúdi sí olódodo.
Tamikalannaw taran lahoi, kâoupnae, hoi matheng laihoi laithoe deinae pahni teh, lawkkamuem lah o sak lah awm seh.
19 Báwo ni títóbi oore rẹ̀ ti pọ̀ tó, èyí tí ìwọ ti ní ní ìpamọ́ fún àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ, èyí tí ìwọ rọ̀jò rẹ̀ níwájú àwọn ènìyàn tí wọ́n fi ọ́ ṣe ibi ìsádi wọn.
Oe nang kataketnaw hanelah, na pâkhueng e hoi tami capanaw mithmu vah, nang kâuepnaw hanelah, na noe e na hawinae hah banghloimaw a bawilen.
20 Ní abẹ́ ìbòòji iwájú rẹ ni ìwọ pa wọ́n mọ́ sí kúrò nínú ìdìmọ̀lù àwọn ènìyàn; ní ibùgbé rẹ, o mú wọn kúrò nínú ewu kúrò nínú ìjà ahọ́n.
Taminaw e arulahoi khokhangnae thung hoi, hlout sak nahanelah, ahnimanaw teh, na onae koe na hmalah na hro han. Tamthoe kadeinaw e lai dawk hoi na rungngang vaiteh, na rim dawk na hro han.
21 Olùbùkún ni Olúwa, nítorí pé ó ti fi àgbà ìyanu ìfẹ́ tí ó ní sí mi hàn, nígbà tí mo wà ní ìlú tí wọ́n rọ̀gbà yíká.
BAWIPA teh pholen lah awm seh. Bangkongtetpawiteh, kângairu a pahrennae teh, kacakpounge khopui dawk na hmu sak.
22 Èmí ti sọ nínú ìdágìrì mi, “A gé mi kúrò ní ojú rẹ!” Síbẹ̀ ìwọ ti gbọ́ ẹ̀bẹ̀ mi fún àánú nígbà tí mo ké pè ọ́ fún ìrànlọ́wọ́.
Bangkongtetpawiteh, kai teh na mithmu vah, tâkhawng lah yo ka o toe telah tang ka dei. Hatei, ka hram teh pahrennae ka hei e lawk hah na thai.
23 Ẹ fẹ́ Olúwa, gbogbo ẹ̀yin ènìyàn rẹ̀ mímọ́! Olúwa pa olódodo mọ́, ó sì san án padà fún agbéraga ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́.
Oe tamikathoungnaw pueng, BAWIPA teh lungpataw awh. Bangkongtetpawiteh, BAWIPA ni yuemkamcu e hah a khetyawt teh, kâoupnaw hah moi a pathung.
24 Jẹ́ alágbára, yóò sì mú yín ní àyà le gbogbo ẹ̀yin tí ó dúró de Olúwa.
BAWIPA kâuepnaw pueng, tarankahawi lah awm awh, na lungthin a thao sak han.

< Psalms 31 >