< Psalms 31 >

1 Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Nínú rẹ̀, Olúwa ni mo ti rí ààbò; má ṣe jẹ́ kí ojú kí ó tì mí; gbà mí nínú òdodo rẹ.
Hina Gode! Na da Dia gaga: ma: ne Dima maha. Dia na enoga maedafa hasalasima: ma. Di da moloidafa Gode. Na da Dima sia: ne gadosa! Na gaga: ma!
2 Tẹ́ etí rẹ sí mi, gbà mí kíákíá; jẹ́ àpáta ààbò mi, jẹ́ odi alágbára láti gbà mí.
Na sia: nabima! Wahadafa na gaga: ma! Na gaga: ma: ne, fedege agoane Dia na dabe fasa: besa: le sogebi dialoma!
3 Ìwọ pàápàá ni àpáta àti ààbò mi, nítorí orúkọ rẹ, máa ṣe olùtọ́ mi, kí o sì ṣe amọ̀nà mi.
Dia da na gado sogebi amola na gaga: su gala. Dia sia: i ilegei defele, nama logo olelema amola amoga na oule masa.
4 Yọ mí jáde kúrò nínú àwọ̀n tí wọ́n dẹ pamọ́ fún mi, nítorí ìwọ ni ìsádi mi.
Na sa: ima: ne sanenisi dialebe amoga dasa: besa: le, na fidima. Se nabasu da nama doagasa: besa: le, na ougihalesima.
5 Ní ọwọ́ rẹ ni mo fi ẹ̀mí mi lé; ìwọ ni o ti rà mí padà, Olúwa, Ọlọ́run òtítọ́.
Hina Gode! Na da Dia ouligisu hou amoga ouligima: ne Dima yolesimu. Di da na gaga: mu. Bai Di da mae fisili didili hamosu Gode.
6 Èmi ti kórìíra àwọn ẹni tí ń fiyèsí òrìṣà tí kò níye lórí; ṣùgbọ́n èmi gbẹ́kẹ̀lé Olúwa.
Di da ogogole ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadobe dunu, ili higasa. Be na da Dima dafawaneyale dawa: sa.
7 Èmi yóò yọ̀, inú mi yóò dùn nínú ìfẹ́ ńlá rẹ, nítorí ìwọ ti rí ìbìnújẹ́ mi ìwọ ti mọ̀ ọkàn mi nínú ìpọ́njú.
Di da nama maedafa fisili asigi hou dialebeba: le, na hahawane amola obenai dialumu. Di da na hahanibi amo ba: sa amola na bidi hamoi amo huluane Dia dawa:
8 Pẹ̀lú, ìwọ kò sì fà mi lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́ ìwọ ti fi ẹsẹ̀ mi lé ibi ààyè ńlá.
Di da nama ha lai dunu da na doagala: le fedele lama: ne hame hamoi. Di da nama soge na hanai amoga udigili laloma: ne nama sia: i dagoi.
9 Ṣàánú fún mi, ìwọ Olúwa, nítorí mo wà nínú ìpọ́njú; ojú mi fi ìbìnújẹ́ sùn, ọkàn àti ara mi pẹ̀lú.
Hina Gode! Nama asigima! Bai na da bidi hamosu amo ganodini esalebe ba: sa. Na si da dinana helesa. Na da helei baligili nabi dagoi.
10 Èmi fi ìbànújẹ́ lo ọjọ́ mi àti àwọn ọdún mi pẹ̀lú ìmí ẹ̀dùn; agbára mi ti kùnà nítorí òsì mi, egungun mi sì ti rún dànù.
Na da da: i dioiba: le, helele ha: ha: i dagoi. Dinanasu da na esalusu dunumuginisi dagoi. Na bidi hamosu bagade ba: beba: le, gasa hamedei gala. Na gasa amolawane da wadela: lala.
11 Èmi di ẹni ẹ̀gàn láàrín àwọn ọ̀tá mi gbogbo, pẹ̀lúpẹ̀lú láàrín àwọn aládùúgbò mi, mo sì di ẹ̀rù fún àwọn ojúlùmọ̀ mi; àwọn tí ó rí mi ní òde ń yẹra fún mi.
Nama ha lai dunu huluane, amola na gadenene dunu iliamusu, nama higale ba: sa. Dunu oda na dawa: dunu da naba: le beda: sa. Ilia da na logoa ba: sea, hobeale afia: sa.
12 Èmi ti di ẹni ìgbàgbé kúrò ní ọkàn gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ó ti kú; èmi sì dàbí ohun èlò tí ó ti fọ́.
Dunu huluane ilia da na bogoiyale, gogolele fisi dagoi. Ilia na galagai liligi agoai ba: sa.
13 Nítorí mo gbọ́ ọ̀rọ̀ ẹ̀gàn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìpayà tí ó yí mi ká; tí wọn gbìmọ̀ pọ̀ sí mi, wọ́n sì ṣọ̀tẹ̀ sí mi láti gba ẹ̀mí mi.
Nama ha lai dunu bagohame ilia nama sadoga sia: dalebe, na naba. Na da bagadewane beda: i. Nama ha lai dunu da na fane legemusa: , sia: ilegesa.
14 Ṣùgbọ́n èmí gbẹ́kẹ̀lé ọ, ìwọ Olúwa; mo sọ wí pé, “Ìwọ ní Ọlọ́run mi.”
Be Hina Gode! Na da Dima dafawaneyale dawa: sa. Bai Di da na Godedafa.
15 Ìgbà mi ń bẹ ní ọwọ́ rẹ; gbà mí kúrò ní ọwọ́ àwọn ọ̀tá mi àti àwọn onínúnibíni.
Na da eso huluane Dia ouligibi hou ganodini esala. Nama ha lai dunu, amo da nama se bagade iaha, ilia da na wadela: sa: besa: le, Dia gaga: ma.
16 Jẹ́ kí ojú rẹ kí ó tan ìmọ́lẹ̀ sí ìránṣẹ́ rẹ lára; gbà mí nínú ìfẹ́ rẹ tí ó dúró ṣinṣin.
Na da Dia hawa: hamosu dunu. Nama asigiwane ba: ma! Dia mae fisili asigi hou amoga na gaga: ma.
17 Má ṣe jẹ́ kí ojú ki ó tì mí, Olúwa; nítorí pé mo ké pè ọ́; jẹ́ kí ojú kí ó ti ènìyàn búburú; jẹ́ kí wọ́n lọ pẹ̀lú ìdààmú sí isà òkú. (Sheol h7585)
Hina Gode! Na da Dima wele sia: sa! Na da mae gogosiasu hamoma: ma! Be wadela: i hamosu dunu ilia gogosiasu ba: mu da defea. Ilia da ouiya: lewane bogosu sogebi amo gudu sa: imu da defea. (Sheol h7585)
18 Jẹ́ kí àwọn ètè irọ́ kí ó dákẹ́ jẹ́ẹ́, pẹ̀lú ìgbéraga àti ìkẹ́gàn, wọ́n sọ̀rọ̀ àfojúdi sí olódodo.
Gasa fi nimi bagade dunu da moloidafa dunu ilia hou olelema: ne, ogogole higale sia: sa. Hina Gode! Amo ogogosu dunu ouiya: lesima!
19 Báwo ni títóbi oore rẹ̀ ti pọ̀ tó, èyí tí ìwọ ti ní ní ìpamọ́ fún àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ, èyí tí ìwọ rọ̀jò rẹ̀ níwájú àwọn ènìyàn tí wọ́n fi ọ́ ṣe ibi ìsádi wọn.
Dunu da Dima nodone hamosa, amo da Dia baligili noga: idafa imunusa: momagei dialebe ba: mu. Di da noga: idafa! Amola dunu amo ilia Dima dafawaneyale dawa: sa amo noga: ledafa gaga: sa. Dunu huluane da amo hou dawa:
20 Ní abẹ́ ìbòòji iwájú rẹ ni ìwọ pa wọ́n mọ́ sí kúrò nínú ìdìmọ̀lù àwọn ènìyàn; ní ibùgbé rẹ, o mú wọn kúrò nínú ewu kúrò nínú ìjà ahọ́n.
Eno dunu da ili wadela: ma: ne ilegesa. Be Di da Dia midadi amoga ili gaga: musa: wamolegelesisa. Ilima ha lai dunu da ilima mae gadele sia: ma: ne, Di da ougihai gado amoga ili wamolegesa.
21 Olùbùkún ni Olúwa, nítorí pé ó ti fi àgbà ìyanu ìfẹ́ tí ó ní sí mi hàn, nígbà tí mo wà ní ìlú tí wọ́n rọ̀gbà yíká.
Hina Godema hahawane nodoma! Nama ha lai ilia da na doagala: le, eale sisiga: le disiba: le, E da Ea asigidafa hou nama olelei.
22 Èmí ti sọ nínú ìdágìrì mi, “A gé mi kúrò ní ojú rẹ!” Síbẹ̀ ìwọ ti gbọ́ ẹ̀bẹ̀ mi fún àánú nígbà tí mo ké pè ọ́ fún ìrànlọ́wọ́.
Na da beda: i galu amola na da Ea yolesibala: le dawa: i galu. Be na da Ea fidima: ne dini iabeba: le, E da na dibi nabi.
23 Ẹ fẹ́ Olúwa, gbogbo ẹ̀yin ènìyàn rẹ̀ mímọ́! Olúwa pa olódodo mọ́, ó sì san án padà fún agbéraga ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́.
Hina Godema mae fisili dafawaneyale dawa: su dunu huluane, dilia! Hina Godema asigima! Hi da dili gaga: sa! Be E da gasa fi dunu ilima se bidi iaha. Bai ilia da amo se iasu lamu da defea.
24 Jẹ́ alágbára, yóò sì mú yín ní àyà le gbogbo ẹ̀yin tí ó dúró de Olúwa.
Dilia! Hina Gode da hobea misunu liligi huluane ouligisa. Amo dafawaneyale dawa: su dunu, dilia! Gasa fili, gesa: idafa ba: ma.

< Psalms 31 >