< Psalms 3 >
1 Saamu ti Dafidi. Nígbà ti ó sá fún ọmọ rẹ̀ Absalomu. Olúwa, báwo ni àwọn ọ̀tá mi ṣe pọ̀ tó báyìí! Báwo ni àwọn ti ó dìde sí mi ṣe pọ̀ tó!
Dawut öz oghli Abshalomdin qéchip yürgen künlerde yazghan küy: — I Perwerdigar, méni qistawatqanlar neqeder köpiyip ketken, Men bilen qarshilishiwatqanlar némidégen köp!
2 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó ń sọ ní ti tèmi, pé “Ọlọ́run kò nígbà á là.” (Sela)
Nurghunlar men toghruluq: — «Xudadin uninggha héch nijat yoqtur!» déyishiwatidu. (Sélah)
3 Ṣùgbọ́n ìwọ ni asà yí mi ká, Olúwa; ìwọ fi ògo fún mi, ìwọ sì gbé orí mi sókè.
Biraq Sen, i Perwerdigar, etrapimdiki qalqandursen; Shan-sheripim hem béshimni yöligüchidursen!
4 Olúwa ni mo kígbe sókè sí, ó sì dá mi lóhùn láti orí òkè mímọ́ rẹ̀ wá. (Sela)
Awazim bilen men Perwerdigargha nida qilimen, U muqeddes téghidin ijabet béridu. (Sélah)
5 Èmi dùbúlẹ̀, mo sì sùn; mo sì tún padà jí, nítorí Olúwa ni ó ń gbé mi ró.
Men bolsam yattim, uxlidim; Oyghandim, chünki Perwerdigar manga yar-yölek bolidu.
6 Èmi kì yóò bẹ̀rù ẹgbẹẹgbẹ̀rún ènìyàn tí wọ́n rọ̀gbà yí mi ká.
Méni qorshap sep tüzgen tümenligen ademler bolsimu, Men ulardin qorqmaymen!
7 Dìde, Olúwa! Gbà mí, Ọlọ́run mi! Lu gbogbo àwọn ọ̀tá mi ní àgbọ̀n; kí o sì ká eyín àwọn ènìyàn búburú.
I Perwerdigar, ornungdin tur! Méni qutquz, i Xudayim! Méning barliq düshmenlirimning testikige salghaysen; Rezillerning chishlirini chéqiwetkeysen!
8 Láti ọ̀dọ̀ Olúwa ni ìgbàlà ti wá. Kí ìbùkún rẹ wà lórí àwọn ènìyàn rẹ. (Sela)
Nijatliq bolsa Perwerdigardindur; Berikiting Öz xelqingde bolsun! (Sélah)