< Psalms 3 >

1 Saamu ti Dafidi. Nígbà ti ó sá fún ọmọ rẹ̀ Absalomu. Olúwa, báwo ni àwọn ọ̀tá mi ṣe pọ̀ tó báyìí! Báwo ni àwọn ti ó dìde sí mi ṣe pọ̀ tó!
Psalm Dawidowy, gdy uciekał przed Absalomem, synem swoim. Panie, jako się namnożyło nieprzyjaciół moich! wiele ich powstaje przeciwko mnie.
2 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó ń sọ ní ti tèmi, pé “Ọlọ́run kò nígbà á là.” (Sela)
Wiele ich mówią o duszy mojej: Niemać ten ratunku od Boga. (Sela)
3 Ṣùgbọ́n ìwọ ni asà yí mi ká, Olúwa; ìwọ fi ògo fún mi, ìwọ sì gbé orí mi sókè.
Ale ty, Panie! jesteś tarczą moją, chwałą moją, i wywyższającym głowę moję.
4 Olúwa ni mo kígbe sókè sí, ó sì dá mi lóhùn láti orí òkè mímọ́ rẹ̀ wá. (Sela)
Głosem swym wołałem do Pana, a wysłuchał mię z góry świętej swojej. (Sela)
5 Èmi dùbúlẹ̀, mo sì sùn; mo sì tún padà jí, nítorí Olúwa ni ó ń gbé mi ró.
Jam się układł, i zasnąłem, a ocuciłem się; bo mię Pan podpierał.
6 Èmi kì yóò bẹ̀rù ẹgbẹẹgbẹ̀rún ènìyàn tí wọ́n rọ̀gbà yí mi ká.
Nie ulęknę się wielu tysięcy ludu, którzy się na mię zewsząd zasadzili.
7 Dìde, Olúwa! Gbà mí, Ọlọ́run mi! Lu gbogbo àwọn ọ̀tá mi ní àgbọ̀n; kí o sì ká eyín àwọn ènìyàn búburú.
Powstań, Panie! wybaw mię, Boże mój! albowiemeś ty uderzył w lice wszystkich nieprzyjaciół moich, z zęby niezbożników pokruszyłeś.
8 Láti ọ̀dọ̀ Olúwa ni ìgbàlà ti wá. Kí ìbùkún rẹ wà lórí àwọn ènìyàn rẹ. (Sela)
Od Panać jest wybawienie, a nad ludem twoim błogosławieństwo twoje. (Sela)

< Psalms 3 >