< Psalms 3 >

1 Saamu ti Dafidi. Nígbà ti ó sá fún ọmọ rẹ̀ Absalomu. Olúwa, báwo ni àwọn ọ̀tá mi ṣe pọ̀ tó báyìí! Báwo ni àwọn ti ó dìde sí mi ṣe pọ̀ tó!
He himene na Rawiri, i tona omanga atu i tana tama i a Apoharama. E Ihowa, ano te tini o oku hoariri, he tokomaha te hunga e whakatika mai ana ki ahau.
2 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó ń sọ ní ti tèmi, pé “Ọlọ́run kò nígbà á là.” (Sela)
He tokomaha te mea ana ki toku wairua, hore rawa he whakaoranga mona i te Atua. (Hera)
3 Ṣùgbọ́n ìwọ ni asà yí mi ká, Olúwa; ìwọ fi ògo fún mi, ìwọ sì gbé orí mi sókè.
Ko koe ia, e Ihowa, hei whakangungu rakau moku, hei kororia moku, hei kaiwhakaara i toku matenga.
4 Olúwa ni mo kígbe sókè sí, ó sì dá mi lóhùn láti orí òkè mímọ́ rẹ̀ wá. (Sela)
I karanga toku reo ki a Ihowa: a whakahoki kupu mai ana ia ki ahau i tona maunga tapu. (Hera)
5 Èmi dùbúlẹ̀, mo sì sùn; mo sì tún padà jí, nítorí Olúwa ni ó ń gbé mi ró.
I takoto ahau, i moe; i ara ake ano; na Ihowa hoki ahau i whakamau ake.
6 Èmi kì yóò bẹ̀rù ẹgbẹẹgbẹ̀rún ènìyàn tí wọ́n rọ̀gbà yí mi ká.
E kore ahau e mataku i nga mano tini o te iwi, kua whakatika mai nei ki ahau karopoti noa.
7 Dìde, Olúwa! Gbà mí, Ọlọ́run mi! Lu gbogbo àwọn ọ̀tá mi ní àgbọ̀n; kí o sì ká eyín àwọn ènìyàn búburú.
Whakatika, e Ihowa; whakaorangia ahau, e toku Atua: nau hoki i patu te kauae o oku hoariri katoa; mangungu noa i a koe nga niho o te hunga kino.
8 Láti ọ̀dọ̀ Olúwa ni ìgbàlà ti wá. Kí ìbùkún rẹ wà lórí àwọn ènìyàn rẹ. (Sela)
Na Ihowa te whakaoranga: kei runga i tau iwi tau manaaki. (Hera)

< Psalms 3 >