< Psalms 3 >
1 Saamu ti Dafidi. Nígbà ti ó sá fún ọmọ rẹ̀ Absalomu. Olúwa, báwo ni àwọn ọ̀tá mi ṣe pọ̀ tó báyìí! Báwo ni àwọn ti ó dìde sí mi ṣe pọ̀ tó!
Thaburi ya Daudi Wee Jehova, kaĩ thũ ciakwa nĩ nyingĩ-ĩ! Andũ arĩa manjũkĩrĩire nĩ aingĩ mũno!
2 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó ń sọ ní ti tèmi, pé “Ọlọ́run kò nígbà á là.” (Sela)
Aingĩ nĩ arĩa maraaria ũhoro wakwa, makoiga atĩrĩ, “Ngai ndangĩmũhonokia.”
3 Ṣùgbọ́n ìwọ ni asà yí mi ká, Olúwa; ìwọ fi ògo fún mi, ìwọ sì gbé orí mi sókè.
No rĩrĩ, Wee Jehova nĩwe ngo ya kũngitĩra mĩena yothe; Wee nowe ũũheaga riiri na ũgatũũgĩria mũtwe wakwa.
4 Olúwa ni mo kígbe sókè sí, ó sì dá mi lóhùn láti orí òkè mímọ́ rẹ̀ wá. (Sela)
Ngayagĩra Jehova na mũgambo mũnene, nake akanjĩtĩka arĩ kĩrĩma-inĩ gĩake kĩamũre.
5 Èmi dùbúlẹ̀, mo sì sùn; mo sì tún padà jí, nítorí Olúwa ni ó ń gbé mi ró.
Niĩ ngomaga na ngoona toro; ngacooka ngokĩra rĩngĩ, tondũ Jehova nĩwe ũndũũragia.
6 Èmi kì yóò bẹ̀rù ẹgbẹẹgbẹ̀rún ènìyàn tí wọ́n rọ̀gbà yí mi ká.
Ndingĩĩtigĩra andũ makũmi ma ngiri, acio mehaarĩirie kũnjũkĩrĩra na mĩena yothe.
7 Dìde, Olúwa! Gbà mí, Ọlọ́run mi! Lu gbogbo àwọn ọ̀tá mi ní àgbọ̀n; kí o sì ká eyín àwọn ènìyàn búburú.
Arahũka, Wee Jehova! Wee Ngai wakwa, honokia! Thũ ciakwa ciothe nĩwe ũcigũthĩte thĩa, na ũkoinanga magego ma andũ arĩa aaganu.
8 Láti ọ̀dọ̀ Olúwa ni ìgbàlà ti wá. Kí ìbùkún rẹ wà lórí àwọn ènìyàn rẹ. (Sela)
Ũhonokio uumaga harĩ Jehova. Irathimo ciaku irotũũra na andũ aku.