< Psalms 29 >
1 Saamu ti Dafidi. Ẹ fi fún Olúwa, ẹ̀yin ẹ̀dá ọ̀run, ẹ fi fún Olúwa, ògo àti alágbára.
Dawid dwom. Momfa mma Awurade no, mo ɔsoro abɔde, momfa anuonyam ne tumi mma Awurade.
2 Fi fún Olúwa, àní ògo orúkọ rẹ̀; sin Olúwa nínú ẹwà ìwà mímọ́.
Momfa anuonyam a ɛfata Awurade din mma no; monsɔre Awurade wɔ nʼanuonyam kronkron mu.
3 Ohùn Olúwa n ré àwọn omi kọjá; Ọlọ́run ògo sán àrá, Olúwa san ara.
Awurade nne wɔ nsu no so; anuonyam Nyankopɔn bobɔ mu, Awurade bobɔ mu wɔ nsu akɛse so.
4 Ohùn Olúwa ní agbára; ohùn Olúwa kún fún ọláńlá.
Awurade nne mu wɔ tumi; Awurade nne mu wɔ anuonyam.
5 Ohùn Olúwa fa igi kedari; Olúwa náà ló fọ́ igi kedari Lebanoni ya.
Awurade nne bubu sida; Awurade nne bubu Lebanon sida mu nketenkete
6 Ó mú Lebanoni fo bí i ọmọ màlúù, àti Sirioni bí ọmọ àgbáǹréré.
Ɔma Lebanon huruhuruw te sɛ nantwi ba, na Sirion nso sɛ ɛko ba.
7 Ohùn Olúwa ń ya bí ọwọ́ iná mọ̀nà.
Awurade nne pa ma anyinam gya dɛw.
8 Ohùn Olúwa ń mi aginjù. Olúwa mi aginjù Kadeṣi.
Awurade nne wosow sare so; Awurade wosow Kades sare.
9 Ohùn Olúwa ní ó lọ igi óákù, ó n mú abo àgbọ̀nrín bí, ó sì bọ́ igi igbó sí ìhòhò. Àti nínú tẹmpili rẹ̀ gbogbo ohùn wí pé, “Ògo!”
Awurade nne kyinkyim adum na ɛma kwae yɛ kwaterekwa. Nʼasɔredan mufo nyinaa teɛ mu ka se, “Anuonyam nka Onyankopɔn!”
10 Olúwa jókòó, Ó sì jẹ ọba lórí ìṣàn omi; Olúwa jókòó lórí ìtẹ́ gẹ́gẹ́ bí Ọba títí láéláé.
Awurade di hene wɔ nsuyiri so; wɔasi Awurade hene afebɔɔ.
11 Kí Olúwa fi agbára fún àwọn ènìyàn rẹ̀; bùkún àwọn ènìyàn rẹ̀ pẹ̀lú àlàáfíà.
Awurade ma ne nkurɔfo ahoɔden, na ɔde asomdwoe hyira wɔn. Dwom a wɔto de buee Asɔredan no ano.