< Psalms 29 >

1 Saamu ti Dafidi. Ẹ fi fún Olúwa, ẹ̀yin ẹ̀dá ọ̀run, ẹ fi fún Olúwa, ògo àti alágbára.
Atoloro am’ Iehovà, ry anam-panalolahy, manoloro engeñe naho haozarañe am’Iehovà. Mañengà volonahetse mañeva i tahina’ey, mitalahoa am’ Iehovà ami’ty hafanjakam-piavahañe.
2 Fi fún Olúwa, àní ògo orúkọ rẹ̀; sin Olúwa nínú ẹwà ìwà mímọ́.
3 Ohùn Olúwa n ré àwọn omi kọjá; Ọlọ́run ògo sán àrá, Olúwa san ara.
Ambone’ o ranoo ty fiarañanaña’ Iehovà, mangotroke i Andrianañahare rengeñey; ambone’ rano mihenehene t’Iehovà.
4 Ohùn Olúwa ní agbára; ohùn Olúwa kún fún ọláńlá.
Maozatse ty fiarañanaña’ Iehovà; lifotse volonahetse ty fiarañanaña’ Iehovà.
5 Ohùn Olúwa fa igi kedari; Olúwa náà ló fọ́ igi kedari Lebanoni ya.
Mampipozapozake o tezao ty fiarañanaña’ Iehovà, eka mamatsimpatsike o mendorave’ i Lebanoneo t’Iehovà.
6 Ó mú Lebanoni fo bí i ọmọ màlúù, àti Sirioni bí ọmọ àgbáǹréré.
Ampitsamboañe’e hoe tarabao hoe te anan-drimo t’i Lebanone naho i Sirione.
7 Ohùn Olúwa ń ya bí ọwọ́ iná mọ̀nà.
Mampiriaria lel’ afo ty fiarañanaña’ Iehovà.
8 Ohùn Olúwa ń mi aginjù. Olúwa mi aginjù Kadeṣi.
Ampanginikinihe’ ty fatram-bey ty fiarañanaña’ Iehovà, ampihondrahondrae’ Iehovà ty fatrambei’ i Kadese.
9 Ohùn Olúwa ní ó lọ igi óákù, ó n mú abo àgbọ̀nrín bí, ó sì bọ́ igi igbó sí ìhòhò. Àti nínú tẹmpili rẹ̀ gbogbo ohùn wí pé, “Ògo!”
Mampiterake o dierao ty fiarañanaña’ Iehovà, vaho ampikorendahe’e o alao; le añ’anjomba’e ao, songa miredoñe ty hoe: Engeñe!
10 Olúwa jókòó, Ó sì jẹ ọba lórí ìṣàn omi; Olúwa jókòó lórí ìtẹ́ gẹ́gẹ́ bí Ọba títí láéláé.
Niambesatse ambone’ i fiepoepoañey t’Iehovà. eka miambesatse ho mpanjaka nainai’e t’Iehovà.
11 Kí Olúwa fi agbára fún àwọn ènìyàn rẹ̀; bùkún àwọn ènìyàn rẹ̀ pẹ̀lú àlàáfíà.
Ho tolora’ Iehovà faozarañe ondati’eo; ho tolora’ Iehovà fañanintsiñe ondati’eo.

< Psalms 29 >