< Psalms 29 >
1 Saamu ti Dafidi. Ẹ fi fún Olúwa, ẹ̀yin ẹ̀dá ọ̀run, ẹ fi fún Olúwa, ògo àti alágbára.
Psalmo de David. Tributu al la Eternulo, vi potenculoj, Tributu al la Eternulo honoron kaj forton.
2 Fi fún Olúwa, àní ògo orúkọ rẹ̀; sin Olúwa nínú ẹwà ìwà mímọ́.
Tributu al la Eternulo la honoron de Lia nomo; Kliniĝu antaŭ la Eternulo en sankta ornamo.
3 Ohùn Olúwa n ré àwọn omi kọjá; Ọlọ́run ògo sán àrá, Olúwa san ara.
La voĉo de la Eternulo iras super la akvoj; La Dio de gloro tondras, La Eternulo super grandaj akvoj.
4 Ohùn Olúwa ní agbára; ohùn Olúwa kún fún ọláńlá.
La voĉo de la Eternulo iras kun forto, La voĉo de la Eternulo iras kun majesto.
5 Ohùn Olúwa fa igi kedari; Olúwa náà ló fọ́ igi kedari Lebanoni ya.
La voĉo de la Eternulo rompas cedrojn, La Eternulo rompas la cedrojn de Lebanon.
6 Ó mú Lebanoni fo bí i ọmọ màlúù, àti Sirioni bí ọmọ àgbáǹréré.
Li saltigas ilin kiel bovidon, Lebanonon kaj Sirjonon kiel bubalidon.
7 Ohùn Olúwa ń ya bí ọwọ́ iná mọ̀nà.
La voĉo de la Eternulo elhakas fajran flamon.
8 Ohùn Olúwa ń mi aginjù. Olúwa mi aginjù Kadeṣi.
La voĉo de la Eternulo skuas dezerton, La Eternulo skuas la dezerton Kadeŝ.
9 Ohùn Olúwa ní ó lọ igi óákù, ó n mú abo àgbọ̀nrín bí, ó sì bọ́ igi igbó sí ìhòhò. Àti nínú tẹmpili rẹ̀ gbogbo ohùn wí pé, “Ògo!”
La voĉo de la Eternulo igas cervinojn naski, kaj nudigas arbarojn; Kaj en Lia templo ĉio parolas pri Lia gloro.
10 Olúwa jókòó, Ó sì jẹ ọba lórí ìṣàn omi; Olúwa jókòó lórí ìtẹ́ gẹ́gẹ́ bí Ọba títí láéláé.
La Eternulo regis en la tempo de la diluvo, La Eternulo restos Reĝo eterne.
11 Kí Olúwa fi agbára fún àwọn ènìyàn rẹ̀; bùkún àwọn ènìyàn rẹ̀ pẹ̀lú àlàáfíà.
La Eternulo donos forton al Sia popolo, La Eternulo benos Sian popolon per paco.