< Psalms 26 >

1 Ti Dafidi. Ṣe ìdájọ́ mi, Olúwa, nítorí tí mo ti ń rìn nínú ìwà òtítọ́ ọ̀ mi, mo sì ti ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú Olúwa, ǹjẹ́ ẹsẹ̀ mi kì yóò yẹ̀.
Thaburi ya Daudi Wee Jehova, nduĩra itua rĩa kĩhooto, nĩgũkorwo mĩthiĩre yakwa nĩmĩkindĩrĩku; ndũũrĩte ndĩhokete Jehova itegũthangania.
2 Wádìí mi wò, Ìwọ Olúwa, kí o sì dán mi wò, dán àyà àti ọkàn mi wò;
Wee Jehova, ngeria na ũndorie, tuĩria ngoro yakwa o na meciiria makwa;
3 nítorí ìfẹ́ ẹ̀ rẹ tí ó dúró ṣinṣin ń bẹ níwájú mi, èmí sì ti rìn nínú òtítọ́ rẹ.
nĩgũkorwo wendo waku ũkoragwo ũrĩ mbere yakwa, na ngeragĩra njĩra-inĩ yaku ya ũhoro wa ma.
4 Èmi kò jókòó pẹ̀lú aláìṣòótọ́, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò bá àwọn àgàbàgebè wọlé.
Ndiikaranagia na andũ a maheeni, o na kana ngagwatanĩra na andũ arĩa marĩ ũhinga.
5 Èmi ti kórìíra àwùjọ àwọn ènìyàn búburú èmi kì yóò sì bá àwọn ènìyàn ìkà jókòó.
Nĩthũire kĩũngano kĩa andũ arĩa mekaga ũũru, na ngarega gũikarania na andũ arĩa aaganu.
6 Èmí ó wẹ ọwọ́ mi ní àìlẹ́ṣẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò sì yí pẹpẹ rẹ ká Olúwa.
Ngwĩthamba moko nyonanie ndirĩ na mahĩtia, thiũrũrũke kĩgongona gĩaku, Wee Jehova,
7 Èmi yóò kọrin sókè àní orin ọpẹ́, èmi yóò sì máa sọ iṣẹ́ ìyanu rẹ̀.
nyine nyanĩrĩire rwĩmbo rwa gũcookia ngaatho, na heane ũhoro wa ciĩko ciaku ciothe cia magegania.
8 Háà Olúwa, èmí ń fẹ́ ilé rẹ níbi tí ìwọ ń gbé, àní níbi tí ògo rẹ̀ wà.
Wee Jehova, nĩnyendete nyũmba ĩrĩa ũtũũraga, o handũ harĩa riiri waku ũikaraga.
9 Má ṣe gbá mi dànù pẹ̀lú àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀, tàbí ẹ̀mí mi pẹ̀lú àwọn ọkùnrin tí òǹgbẹ ẹ̀jẹ̀ ń gbẹ,
Ndũkeherie ngoro yakwa hamwe na ya arĩa mehagia, kana muoyo wakwa hamwe na wa andũ arĩa maitaga thakame,
10 àwọn tí ọwọ́ wọn kún fún ìwà ibi, tí ọwọ́ ọ̀tún wọn kún fún àbẹ̀tẹ́lẹ̀.
arĩa marĩ na maũndũ ma waganu moko-inĩ mao, o arĩa moko mao ma ũrĩo maiyũrĩte mahaki.
11 Ṣùgbọ́n èmi ó máa rìn nínú ìwà títọ́; rà mí padà, kí o sì ṣàánú fún mi.
No niĩ-rĩ, ndũũraga mũtũũrĩre ũtarĩ ũcuuke; kĩngũũre na ũnjiguĩre tha.
12 Ẹsẹ̀ mi dúró lórí ilẹ̀ tí ó tẹ́jú; nínú ìjọ ńlá èmi yóò fi ìbùkún fún Olúwa.
Magũrũ makwa marũgamĩte handũ harĩa haigananu; nĩndĩrĩgoocaga Jehova ndĩ kĩũngano-inĩ kĩnene.

< Psalms 26 >