< Psalms 26 >
1 Ti Dafidi. Ṣe ìdájọ́ mi, Olúwa, nítorí tí mo ti ń rìn nínú ìwà òtítọ́ ọ̀ mi, mo sì ti ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú Olúwa, ǹjẹ́ ẹsẹ̀ mi kì yóò yẹ̀.
David kah Aw BOEIPA, kai he lai han tloek lah. Thincaknah neh ka cet tih BOEIPA te ka pangtung dongah ka dinghae pawh.
2 Wádìí mi wò, Ìwọ Olúwa, kí o sì dán mi wò, dán àyà àti ọkàn mi wò;
Aw BOEIPA kai he n'loepdak lamtah kai n'noemcai lah. Ka kuel neh lungbuei he picai la picai mai.
3 nítorí ìfẹ́ ẹ̀ rẹ tí ó dúró ṣinṣin ń bẹ níwájú mi, èmí sì ti rìn nínú òtítọ́ rẹ.
Ka mik dongah na sitlohnah ka hmaitang tih na oltak dongah ka cet.
4 Èmi kò jókòó pẹ̀lú aláìṣòótọ́, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò bá àwọn àgàbàgebè wọlé.
Hlang taengah a poeyoek la ka ngol pawt tih aka thuhrhawk neh ka yok pawh.
5 Èmi ti kórìíra àwùjọ àwọn ènìyàn búburú èmi kì yóò sì bá àwọn ènìyàn ìkà jókòó.
Thaehuet rhoek kah a ngolhlung te ka thiinah tih halang rhoek taengah ka ngol pawh.
6 Èmí ó wẹ ọwọ́ mi ní àìlẹ́ṣẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò sì yí pẹpẹ rẹ ká Olúwa.
Ka kut he cimnah neh ka silh tih, BOEIPA nang kah hmueihtuk te ka hil he,
7 Èmi yóò kọrin sókè àní orin ọpẹ́, èmi yóò sì máa sọ iṣẹ́ ìyanu rẹ̀.
Uemonah ol te ka doek tih namah kah khobaerhambae boeih te ka tae.
8 Háà Olúwa, èmí ń fẹ́ ilé rẹ níbi tí ìwọ ń gbé, àní níbi tí ògo rẹ̀ wà.
Aw BOEIPA, na lum-im khuirhung neh na thangpomnah dungtlungim hmuen te ka lungnah.
9 Má ṣe gbá mi dànù pẹ̀lú àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀, tàbí ẹ̀mí mi pẹ̀lú àwọn ọkùnrin tí òǹgbẹ ẹ̀jẹ̀ ń gbẹ,
Ka hinglu he hlangtholh rhoek neh, ka hingnah he thii aka hal hlang rhoek taengla coi boeh.
10 àwọn tí ọwọ́ wọn kún fún ìwà ibi, tí ọwọ́ ọ̀tún wọn kún fún àbẹ̀tẹ́lẹ̀.
Amih kut dongah boethae om tih a bantang kut ah kapbaih a poem uh.
11 Ṣùgbọ́n èmi ó máa rìn nínú ìwà títọ́; rà mí padà, kí o sì ṣàánú fún mi.
Tedae kai tah kamah thincaknah neh ka cet. Kai n'lat lamtah kai n'rhen lah.
12 Ẹsẹ̀ mi dúró lórí ilẹ̀ tí ó tẹ́jú; nínú ìjọ ńlá èmi yóò fi ìbùkún fún Olúwa.
Ka kho he tlangkol ah pai tih khangkhung lakli ah BOEIPA te a yoethen pai ni.