< Psalms 24 >

1 Ti Dafidi. Saamu. Ti Olúwa ni ilẹ̀, àti ẹ̀kún rẹ̀, ayé àti àwọn tí ó tẹ̀dó sínú rẹ̀;
He himene na Rawiri. No Ihowa te whenua, me ona tini mea, te ao, me nga tangata e noho ana i runga.
2 nítorí ó fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ lélẹ̀ lórí òkun ó sì gbé e kalẹ̀ lórí àwọn ìṣàn omi.
He mea whakatu hoki nana ki runga ki nga moana, he mea whakau ki runga ki nga roma.
3 Ta ni yóò gun orí òkè Olúwa lọ? Ta ni yóò dúró ní ibi mímọ́ rẹ̀?
Ko wai e eke ki te maunga o Ihowa? Ko wai e tu ki tona wahi tapu?
4 Ẹni tí ó ní ọwọ́ mímọ́ àti àyà funfun, ẹni tí kò gbé ọkàn rẹ̀ sókè sí asán tí kò sì búra èké.
Ko te tangata he ma nei nga ringa, he harakore tona ngakau, kahore nei i ara tona wairua ki te horihori, a kahore i oati teka.
5 Òun ni yóò rí ìbùkún gbà láti ọ̀dọ̀ Olúwa, àti òdodo lọ́wọ́ Ọlọ́run ìgbàlà rẹ̀.
Ka riro i a ia te manaaki a Ihowa, me te tika a te Atua o tona whakaoranga.
6 Èyí ni ìran àwọn tí ń ṣe àfẹ́rí rẹ̀, tí ń ṣe àfẹ́rí rẹ̀, Ọlọ́run Jakọbu. (Sela)
Ko te whakatupuranga tenei o te hunga e rapu ana ki a ia, e rapu nei i tou mate, e Hakopa. (Hera)
7 Ẹ gbé orí yín sókè, háà! Ẹ̀yin ọ̀nà; kí á sì gbe yín sókè, ẹyin ìlẹ̀kùn ayérayé! Kí ọba ògo le è wọlé.
Kia ara o koutou matenga, e nga tatau, ara ake, e nga tatau onamata; a ka tomo te Kingi o te kororia.
8 Ta ni ọba ògo náà? Olúwa tí ó lágbára tí ó sì le, Olúwa gan an, tí ó lágbára ní ogun.
Ko wai tenei Kingi kororia? Ko Ihowa, ko te kaha, ko te marohirohi, ko Ihowa, ko te marohirohi ki te whawhai.
9 Gbé orí yín sókè, ẹyin ọ̀nà; kí a sì gbé e yín sókè, ẹ̀yin ìlẹ̀kùn ayérayé, kí Ọba ògo le è wọlé wá.
Kia ara o koutou matenga, e nga tatau, kia ara ake, e nga tatau onamata, a ka tomo te Kingi o te kororia.
10 Ta ni Ọba ògo náà? Olúwa àwọn ọmọ-ogun Òun ni Ọba ògo náà. (Sela)
Ko wai tenei Kingi kororia? Ko Ihowa o nga mano, ko ia te Kingi kororia. (Hera)

< Psalms 24 >