< Psalms 24 >

1 Ti Dafidi. Saamu. Ti Olúwa ni ilẹ̀, àti ẹ̀kún rẹ̀, ayé àti àwọn tí ó tẹ̀dó sínú rẹ̀;
Thaburi ya Daudi Thĩ nĩ ya Jehova, na kĩrĩa gĩothe kĩrĩ thĩinĩ wayo, mabũrũri mothe o na arĩa matũũraga kuo;
2 nítorí ó fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ lélẹ̀ lórí òkun ó sì gbé e kalẹ̀ lórí àwọn ìṣàn omi.
nĩgũkorwo nĩwe waakire mũthingi wayo igũrũ rĩa maria, na akĩmĩrũmia ĩikare igũrũ rĩa maaĩ.
3 Ta ni yóò gun orí òkè Olúwa lọ? Ta ni yóò dúró ní ibi mímọ́ rẹ̀?
Nũũ ũngĩambata kĩrĩma-inĩ kĩa Jehova? Nũũ ũngĩrũgama handũ harĩa hake haamũre?
4 Ẹni tí ó ní ọwọ́ mímọ́ àti àyà funfun, ẹni tí kò gbé ọkàn rẹ̀ sókè sí asán tí kò sì búra èké.
Nĩ mũndũ ũrĩa ũrĩ na moko matheru na akaaga ũũru ngoro, na ũrĩa ngoro yake ĩtahooyaga mũhianano, o na kana akeehĩta na maheeni.
5 Òun ni yóò rí ìbùkún gbà láti ọ̀dọ̀ Olúwa, àti òdodo lọ́wọ́ Ọlọ́run ìgbàlà rẹ̀.
Mũndũ ũcio nĩarĩamũkagĩra kĩrathimo kuuma kũrĩ Jehova, na onagwo atarĩ mũhĩtia nĩ Ngai, Mũhonokia wake.
6 Èyí ni ìran àwọn tí ń ṣe àfẹ́rí rẹ̀, tí ń ṣe àfẹ́rí rẹ̀, Ọlọ́run Jakọbu. (Sela)
Ũguo nĩguo rũciaro rwa arĩa mamũrongoragia rũtariĩ, o rũrĩa rũrongoragia ũthiũ waku, Wee Ngai wa Jakubu.
7 Ẹ gbé orí yín sókè, háà! Ẹ̀yin ọ̀nà; kí á sì gbe yín sókè, ẹyin ìlẹ̀kùn ayérayé! Kí ọba ògo le è wọlé.
Ambarariai mĩtwe yanyu, inyuĩ ihingo ici, ambararioi inyuĩ mĩrango ĩno ya tene, nĩguo Mũthamaki wa riiri atoonye thĩinĩ.
8 Ta ni ọba ògo náà? Olúwa tí ó lágbára tí ó sì le, Olúwa gan an, tí ó lágbára ní ogun.
Mũthamaki ũcio wa riiri nĩwe ũũ? Nĩwe Jehova ũrĩa ũrĩ hinya na nĩ njamba, nĩwe Jehova ũrĩa njamba ita-inĩ.
9 Gbé orí yín sókè, ẹyin ọ̀nà; kí a sì gbé e yín sókè, ẹ̀yin ìlẹ̀kùn ayérayé, kí Ọba ògo le è wọlé wá.
Ambarariai mĩtwe yanyu, inyuĩ ihingo ici, mĩambarariei inyuĩ mĩrango ĩno ya tene, nĩguo Mũthamaki wa riiri atoonye thĩinĩ.
10 Ta ni Ọba ògo náà? Olúwa àwọn ọmọ-ogun Òun ni Ọba ògo náà. (Sela)
Mũthamaki ũcio wa riiri nĩwe ũ? Jehova Mwene-Hinya-Wothe-rĩ, nĩwe Mũthamaki wa riiri.

< Psalms 24 >