< Psalms 23 >

1 Saamu ti Dafidi. Olúwa ni olùṣọ́ èmi àgùntàn rẹ̀, èmi kì yóò ṣe aláìní.
Dawut yazghan küy: — Perwerdigar méni baqquchi Padichimdur, Mohtaj emesmen héch nersige;
2 Ó mú mi dùbúlẹ̀ sí ibi pápá oko tútù, Ó mú mi lọ sí ibi omi dídákẹ́ rọ́rọ́,
U méni yumran chöplerde yatquzup dem aldurar; Tinch aqidighan sularni boylitip baqidu;
3 Ó mú ọkàn mi padà bọ̀ sípò. Ó mú mi lọ sí ọ̀nà òdodo nítorí orúkọ rẹ̀.
U wujudumni yéngilaydu; U heqqaniyliq yolida Öz nami üchün yétekleydu;
4 Bí mo tilẹ̀ ń rìn láàrín àfonífojì òjìji ikú, èmi kì yóò bẹ̀rù ibi kan, nítorí ìwọ wà pẹ̀lú mi; ọ̀gọ rẹ àti ọ̀pá à rẹ, wọ́n ń tù mí nínú.
Hetta men ölüm sayisi bolghan jilghidin ötsemmu, Héch yamanliqtin qorqmaymen; Chünki Sen men bilen billidursen; Séning hasang hem tayiqing manga tesellidur.
5 Ìwọ tẹ́ tábìlì oúnjẹ sílẹ̀ níwájú mi ní ojú àwọn ọ̀tá à mi. Ìwọ ta òróró sí mi ní orí; ago mí sì kún àkúnwọ́sílẹ̀.
Méni xar qilghuchilarning köz aldida manga keng dastixan salisen; Méning béshimni may bilen mesih qilisen; Qedehim tashidu;
6 Nítòótọ́, ìre àti àánú ni yóò máa tọ̀ mí lẹ́yìn ní ọjọ́ ayé è mi gbogbo, èmi yóò sì máa gbé inú ilé Olúwa títí láéláé.
Berheq, barliq künlirimde yaxshiliq we özgermes shepqet manga egiship hemrah bolidu; Menggüdin-menggüge Perwerdigarning dergahida yashaymen!

< Psalms 23 >