< Psalms 23 >

1 Saamu ti Dafidi. Olúwa ni olùṣọ́ èmi àgùntàn rẹ̀, èmi kì yóò ṣe aláìní.
Thaburi ya Daudi Jehova nĩwe mũrĩithi wakwa, ndirĩ kĩndũ ingĩaga.
2 Ó mú mi dùbúlẹ̀ sí ibi pápá oko tútù, Ó mú mi lọ sí ibi omi dídákẹ́ rọ́rọ́,
Atũmaga njarahe ũrĩithio-inĩ ũrĩ nyeki nduru, aandongoragia maaĩ-inĩ marĩ na ũhurũko.
3 Ó mú ọkàn mi padà bọ̀ sípò. Ó mú mi lọ sí ọ̀nà òdodo nítorí orúkọ rẹ̀.
Nĩariũkagia ngoro yakwa, akandongoragia njĩra-inĩ cia ũthingu, nĩ ũndũ wa rĩĩtwa rĩake.
4 Bí mo tilẹ̀ ń rìn láàrín àfonífojì òjìji ikú, èmi kì yóò bẹ̀rù ibi kan, nítorí ìwọ wà pẹ̀lú mi; ọ̀gọ rẹ àti ọ̀pá à rẹ, wọ́n ń tù mí nínú.
O na ingĩtuĩka ndĩrahungurĩra mũkuru ũrĩ nduma ta ya gĩkuũ, ndirĩ ũũru ingĩĩtigĩra, nĩgũkorwo ũrĩ hamwe na niĩ; thiarĩ waku na mũthĩgi waku nĩciihooreragia.
5 Ìwọ tẹ́ tábìlì oúnjẹ sílẹ̀ níwájú mi ní ojú àwọn ọ̀tá à mi. Ìwọ ta òróró sí mi ní orí; ago mí sì kún àkúnwọ́sílẹ̀.
Ũnjaragĩra metha mbere yakwa o harĩa thũ ciakwa irĩ. Ũnjitagĩrĩria maguta mũtwe; gĩkombe gĩakwa nĩkĩiyũrĩrĩire.
6 Nítòótọ́, ìre àti àánú ni yóò máa tọ̀ mí lẹ́yìn ní ọjọ́ ayé è mi gbogbo, èmi yóò sì máa gbé inú ilé Olúwa títí láéláé.
Ti-itherũ wega na wendani nĩirĩrũmanagĩrĩra na niĩ matukũ mothe ma muoyo wakwa, na niĩ ngũtũũra nyũmba ya Jehova nginya tene.

< Psalms 23 >