< Psalms 23 >

1 Saamu ti Dafidi. Olúwa ni olùṣọ́ èmi àgùntàn rẹ̀, èmi kì yóò ṣe aláìní.
David kah Tingtoenglung BOEIPA loh kai n'dawn dongah, m'vaitah mahpawh.
2 Ó mú mi dùbúlẹ̀ sí ibi pápá oko tútù, Ó mú mi lọ sí ibi omi dídákẹ́ rọ́rọ́,
Toitlim annoe ah kai n'kol sak tih, duemnah tui taengla kai n'khool.
3 Ó mú ọkàn mi padà bọ̀ sípò. Ó mú mi lọ sí ọ̀nà òdodo nítorí orúkọ rẹ̀.
Ka hinglu han thoelh tih, amah ming ham duengnah namtlak ah kai m'mawt
4 Bí mo tilẹ̀ ń rìn láàrín àfonífojì òjìji ikú, èmi kì yóò bẹ̀rù ibi kan, nítorí ìwọ wà pẹ̀lú mi; ọ̀gọ rẹ àti ọ̀pá à rẹ, wọ́n ń tù mí nínú.
Dueknah hlipkhup kolrhawk ah ka caeh vaengah pataeng, nang loh namah kah mancai neh kai nan om puei tih, na conghol loh kai n'hloep dongah yoethaenah khaw ka rhih pawh.
5 Ìwọ tẹ́ tábìlì oúnjẹ sílẹ̀ níwájú mi ní ojú àwọn ọ̀tá à mi. Ìwọ ta òróró sí mi ní orí; ago mí sì kún àkúnwọ́sílẹ̀.
Kai aka daengdaeh hmaiah pataeng, kai mikhmuh ah caboei nan tawn. Ka lu he situi neh na men sak tih, ka boengloeng he a coihdanah om.
6 Nítòótọ́, ìre àti àánú ni yóò máa tọ̀ mí lẹ́yìn ní ọjọ́ ayé è mi gbogbo, èmi yóò sì máa gbé inú ilé Olúwa títí láéláé.
Ka hingnah tue puet te, hnothen neh sitlohnah bueng loh kai n'hloem saeh lamtah, BOEIPA im ah khohnin takuem kho ka sa eh.

< Psalms 23 >