< Psalms 22 >

1 Fún adarí orin. Tí ohùn orin “àgbọ̀nrín òwúrọ̀.” Saamu ti Dafidi. Ọlọ́run mi, Ọlọ́run mi, èéṣe tí ìwọ fi kọ̀ mí sílẹ̀? Èéṣe tí o fi jìnnà láti gbà mí là, àní sí igbe ìkérora mi?
Kathutkung: Devit Ka Cathut, ka Cathut, bangkongmaw na cei takhai. Bangkongmaw ka kâhramnae lawk thai laipalah, na kabawp hoeh nahanlah ahlanae koe na o.
2 Ọlọ́run mi, ní ọ̀sán gangan ni mo kígbe, ṣùgbọ́n ìwọ kò dá mi ní ohùn: àti ní òru èmi kò dákẹ́.
Oe Cathut, khodai lah kâhram ei, nang ni na thai pouh hoeh. Karum lahai duem ka onae awm hoeh.
3 Ṣùgbọ́n síbẹ̀ ẹni mímọ́ ni Ìwọ; ẹni tí ó tẹ ìyìn Israẹli dó.
Hatei, nang teh, na thoung. Isarelnaw ni pholen e lah na o.
4 Àwọn baba ńlá wa ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú rẹ; wọ́n ní ìgbẹ́kẹ̀lé, ìwọ sì gbà wọ́n.
Ka mintoenaw ni na kâuep teh, na rungngang.
5 Ìwọ ni wọ́n sun ẹkún sí, wọ́n sì ní ìgbàlà; ìwọ ni wọ́n gbẹ́kẹ̀lé, a kò sì dójútì wọ́n.
Na kaw awh teh, na rungngang. Na kâuep awh teh, yeiraipo boi awh hoeh.
6 Ṣùgbọ́n kòkòrò ní mo jẹ́, kì í sì í ṣe ènìyàn; mo di ẹlẹ́gàn àwọn ènìyàn, ẹlẹ́yà àwọn ènìyàn.
Hatei, kai teh tangraet lah doeh ka o. Ayâ ni pathoe e hoi pacekpahlek e lah ka o.
7 Gbogbo àwọn tí ó rí mí fi mí ṣe ẹlẹ́yà; wọ́n yọ ètè ẹ̀gàn wọn sí mi, wọ́n sì ń mi orí wọn pé.
Na ka hmawt e pueng ni na panuikhai, a pahni na ke sin awh. A lû na saling sin awh.
8 “Ó gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ lé Olúwa; jẹ́ kí Olúwa gbà á là. Jẹ́ kí ó gbà á là, nítorí pé, ó ní ayọ̀ nínú rẹ̀.”
BAWIPA a kâuep nahoehmaw, ama ni rungngang na haw seh. Ahni dawk a ngainae awm pawiteh, atu roeroe rungngang na haw seh, telah ati awh.
9 Síbẹ̀ ìwọ ni ó ti mú mi wá láti inú; ìwọ ni ó mú mi wà láìléwu, nígbà tí mo rọ̀ mọ́ ọmú ìyá mi.
Hatei, nang teh anu von thung hoi na karasatkung doeh. Sanu ka nei lahun nah puennae na takhoe pouh.
10 Ìwọ ni a fi mí lé lọ́wọ́ láti inú ìyá mi wá, nígbà tí ìyá mí sì ti bí mi, ìwọ ni Ọlọ́run mi.
Pek khe hoi nang dawk hruek e lah ka o. Anu von thung hoi patenghai, nang teh ka Cathut lah yo la na o toe.
11 Má ṣe jìnnà sí mi, nítorí pé ìyọnu súnmọ́ tòsí kò sì ṣí ẹnìkan tí yóò ṣe ìrànlọ́wọ́.
Kai koehoi ahlanae koe awm hanh. Bangkongtetpawiteh, runae a hnai teh kabawmkung awm hoeh.
12 Ọ̀pọ̀ akọ màlúù yí mi ká; àwọn màlúù alágbára Baṣani rọ̀gbà yí mi ká.
Maitotan moikapap ni na kalup. Bashan ram e athakaawme maitotannaw ni na kalup.
13 Wọ́n ya ẹnu wọn sì mi bí i kìnnìún tí ń dọdẹ kiri, tí ń ké ramúramù.
A pahni na ang sin awh teh, sendek patetlah a cairing awh.
14 A dà mí jáde gẹ́gẹ́ bí omi, gbogbo egungun mi ti yẹ̀ kúrò ní oríkèé rẹ̀. Ọkàn mi sì dàbí i ìda; tí ó yọ́ láàrín inú mi.
Tui patetlah rabawk lah ka o teh, ka hruhrawng pueng teh koung a kâla. Ka lungthin teh khoilai patetlah ka thung vah, a kamyawt toe.
15 Agbára mí ti gbẹ bí àpáàdì, ahọ́n mí sì tilẹ̀ mọ́ párí ẹ̀rẹ̀kẹ́ ẹ mi; ìwọ ti tẹ́ mi sínú eruku ikú. (questioned)
Ka tharui teh ampaikei patetlah a ke teh, ka lai hai ka dangka dawk a kâbet teh, duenae vaiphu dawk na ceikhai.
16 Àwọn ajá yí mi ká; ìjọ àwọn ènìyàn ibi ti ká mi mọ́, wọ́n gún mi lọ́wọ́, wọ́n sì gún mi lẹ́sẹ̀.
Bangkongtetpawiteh, uinaw ni na kalup awh. Tamikathoutnaw ni na kalup awh. Ka kut hoi ka khok pawkkayawng lah a thut awh.
17 Mo lè ka gbogbo àwọn egungun mi; àwọn tìkára wọn ń wò, wọ́n dójú lé mi.
Ka hru pueng koung ka touk thai. Pout laipalah na khet awh teh, a lungkhuekti awh.
18 Wọ́n pín aṣọ mi láàrín ara wọn àní lórí aṣọ mi ni wọ́n ṣẹ́ gègé.
Ka khohna a kârei awh teh, ka angki hah cungpam a rayu awh.
19 Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, má ṣe jìnnà sí mi. Háà! Olùrànlọ́wọ́ ọ̀ mi, yára wá fún àtìlẹ́yìn mi!
Oe BAWIPA na hlat takhai hanh. Oe ka thaonae karanglah na kabawm haw.
20 Gba ọkàn mi sílẹ̀ lọ́wọ́ idà, àní ẹ̀mí mi lọ́wọ́ agbára àwọn ajá.
Senehmaica hoi na rungngang haw, ka hringnae ka sungren e heh uinaw thaonae koehoi na rungngang haw.
21 Gba ọkàn mi sílẹ̀ lọ́wọ́ kìnnìún; kí o sì gbà mí sílẹ̀ lọ́wọ́ ìwo àgbáǹréré.
Sendek kâko dawk hoi na rungngang nateh, savi ki dawk hoi na rungngang haw. Na pato leih.
22 Èmi yóò kéde orúkọ rẹ láàrín arákùnrin àti arábìnrin mi; nínú ìjọ ni èmi yóò máa yìn ọ́.
Ka hmaunawnghanaw koe na min ka pâpho vaiteh, kamkhuengnaw koe na pholen han.
23 Ẹ̀yin tí ẹ bẹ̀rù Olúwa, ẹ yìn ín! Gbogbo ẹ̀yin ìran Jakọbu, ẹ fi ògo fún un! Ẹ dìde fún un tẹ̀rù tẹ̀rù, ẹ̀yin irú-ọmọ Israẹli!
Nangmouh BAWIPA kataketnaw, ama teh pholen awh. Jakop catounnaw pueng ama teh tawmrasang awh nateh, Isarel catounnaw pueng ama teh taket awh.
24 Nítorí pé òun kò ṣátá, bẹ́ẹ̀ ni kò sì kórìíra ìpọ́njú àwọn tí a ni lára; kò sì fi ojú rẹ̀ pamọ́ fún mi ṣùgbọ́n ó gbọ́ nígbà tí mo ké pè é.
Bangkongtetpawiteh, runae ka khang e runae hah, dudam hoeh niteh, ahni koehoi a minhmai hai hrawk hoeh. Hatei, ahni koe a hram toteh a thai.
25 Láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni ìyìn mi yóò ti wá nínú àjọ ńlá; ẹ̀jẹ́ rẹ̀ ni èmi yóò san níwájú àwọn tí o bẹ̀rù rẹ̀
Kalen e kamkhuengnae koe ka pholen e teh nang han doeh. Ama kataketnaw hmalah ka lawkkam hah ka kuep sak han.
26 tálákà yóò jẹ yóò sì yó; àwọn tí n wá Olúwa yóò yin jẹ́ kí ẹ̀mí rẹ̀ wà láààyè títí ayérayé!
Tami ka roedeng ni cat vaiteh a von a paha han. Ama katawngnaw ni BAWIPA teh a pholen han. Na lungthin hah pou kâhlaw seh.
27 Gbogbo òpin ayé ni yóò rántí wọn yóò sì yípadà sí Olúwa, àti gbogbo ìdílé orílẹ̀-èdè ni wọn yóò jọ́sìn níwájú rẹ̀,
Talai poutnae pueng ni a pâkuem awh teh, BAWIPA koe a kamlang awh vaiteh, miphun pueng ni na bawk awh han.
28 nítorí ìjọba ni ti Olúwa. Òun ni ó ń pàṣẹ lórí àwọn orílẹ̀-èdè.
Bangkongtetpawiteh, uknaeram teh BAWIPA e doeh. Miphunnaw hah a uk.
29 Bẹ́ẹ̀ náà ni gbogbo àwọn olówó ayé wọn yóò ṣe àsè, wọn yóò sì sìn; gbogbo àwọn tí ó wọ inú ilẹ̀ lọ yóò kúnlẹ̀ ní iwájú rẹ̀ àti ẹni tí kò lè pa ọkàn ara rẹ̀ mọ́ ni ààyè.
Talaivan katawntanaw pueng ni cat awh vaiteh a bawk awh han. Ma e hringnae ring thai awh hoeh. Vaiphu lah ka ban e pueng a hmalah a tabo awh han.
30 Irú-ọmọ rẹ̀ yóò sìn ín; a ó sọ fún àwọn ìran tí ń bọ̀ nípa Olúwa.
Ahnimae catounnaw ni hai a bawk awh vaiteh, catounnaw ni hai BAWIPA e kamthang hah a dei awh han.
31 Wọn yóò polongo òdodo rẹ̀ sí àwọn ọmọ tí a kò tí ì bí, wí pé, òun ni ó ṣe èyí.
A lannae, pâpho hanelah a tho awh vaiteh, khe lah kaawm hane naw koe BAWIPA ni hetheh a sak telah a pâpho awh han.

< Psalms 22 >