< Psalms 20 >

1 Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Kí Olúwa kí ó gbóhùn rẹ ní ọjọ́ ìpọ́njú; kí orúkọ Ọlọ́run Jakọbu kí ó dáàbò bò ọ́.
Nǝƣmiqilǝrning bexiƣa tapxurulup oⱪulsun dǝp, Dawut yazƣan küy: — Külpǝtlik kündǝ Pǝrwǝrdigar sanga ijabǝt ⱪilƣay! Yaⱪupning Hudasining nami seni egizdǝ aman saⱪliƣay!
2 Kí ó rán ìrànlọ́wọ́ sí ọ, láti ibi mímọ́ kí ó sì tì ọ́ lẹ́yìn láti Sioni wá.
U Ɵz muⱪǝddǝs jayidin sanga mǝdǝt ǝwǝtkǝy, Ziondin sanga küq-ⱪuwwǝt bǝrgǝy;
3 Kí ó sì rántí gbogbo ẹbọ rẹ kí ó sì gba ẹbọ sísun rẹ. (Sela)
Barliⱪ «axliⱪ ⱨǝdiyǝ»liringni yad ⱪilƣay, Kɵydürmǝ ⱪurbanliⱪingni ⱪobul ⱪilƣay! (Selaⱨ)
4 Kí ó fi fún ọ gẹ́gẹ́ bi ti èrò ọkàn rẹ kí ó sì mú gbogbo ìmọ̀ rẹ ṣẹ.
Kɵnglüngdiki tǝxnaliⱪlarni sanga ata ⱪilƣay, Kɵnglünggǝ pükkǝn barliⱪ arzuliringni ǝmǝlgǝ axurƣay.
5 Àwa yóò hó fún ayọ̀ nígbà tí o bá di aṣẹ́gun àwa yóò gbé àsíá wa sókè ní orúkọ Ọlọ́run wa. Kí Olúwa kí ó mú gbogbo ìbéèrè rẹ̀ ṣẹ.
Bizlǝr ƣǝlibǝngni tǝbriklǝp tǝntǝnǝ ⱪilimiz, Hudayimizning namida tuƣlirimizni tiklǝymiz; Pǝrwǝrdigar barliⱪ tǝlǝpliringni ǝmǝlgǝ axurƣay!
6 Nísinsin yìí, èmi mọ̀ wí pé, Olúwa pa ẹni àmì òróró rẹ̀ mọ́. Yóò gbọ́ láti ọ̀run mímọ́ rẹ̀ wá pẹ̀lú agbára ìgbàlà ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀.
Ⱨazir bildimki, Pǝrwǝrdigar Ɵzi mǝsiⱨ ⱪilƣinini ⱪutⱪuzidu; Muⱪǝddǝs ǝrxliridin uningƣa ⱪudrǝtlik ⱪutⱪuzƣuqi ⱪolini uzartip jawab beridu.
7 Àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé kẹ̀kẹ́, àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé ẹṣin, ṣùgbọ́n àwa gbẹ́kẹ̀lé orúkọ Olúwa Ọlọ́run wa.
Bǝzilǝr jǝng ⱨarwiliriƣa, Bǝzilǝr atlarƣa [tayinidu]; Biraⱪ biz bolsaⱪ Pǝrwǝrdigar Hudayimizning namini yad etimiz;
8 Wọ́n wólẹ̀, ní eékún, wọ́n sì ṣubú, ṣùgbọ́n àwa dìde, a sì dúró ṣinṣin.
Ular tizi püklinip yiⱪildi; Biraⱪ biz bolsaⱪ, ⱪǝddimizni ruslap tik turimiz.
9 Olúwa, fi ìṣẹ́gun fún ọba! Dá wa lóhùn nígbà tí a bá ń kígbe pè!
I Pǝrwǝrdigar, padixaⱨⱪa ƣǝlibǝ bǝrgǝysǝn; Nida ⱪilƣinimizda bizgǝ ijabǝt ⱪilƣaysǝn!

< Psalms 20 >