< Psalms 20 >
1 Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Kí Olúwa kí ó gbóhùn rẹ ní ọjọ́ ìpọ́njú; kí orúkọ Ọlọ́run Jakọbu kí ó dáàbò bò ọ́.
Thaburi ya Daudi Jehova arogwĩtĩka rĩrĩa ũrĩ mĩnyamaro-inĩ; rĩĩtwa rĩa Ngai wa Jakubu rĩrokũgitĩra.
2 Kí ó rán ìrànlọ́wọ́ sí ọ, láti ibi mímọ́ kí ó sì tì ọ́ lẹ́yìn láti Sioni wá.
Arokũrehere ũteithio kuuma handũ harĩa hake haamũre, na agũtiirĩrĩre arĩ kũu Zayuni.
3 Kí ó sì rántí gbogbo ẹbọ rẹ kí ó sì gba ẹbọ sísun rẹ. (Sela)
Aroririkana magongona maku mothe, na etĩkĩre maruta maku ma njino.
4 Kí ó fi fún ọ gẹ́gẹ́ bi ti èrò ọkàn rẹ kí ó sì mú gbogbo ìmọ̀ rẹ ṣẹ.
Arokũhe maũndũ marĩa ngoro yaku ĩĩrirĩirie, na atũme mĩbango yaku yothe ĩgaacĩre.
5 Àwa yóò hó fún ayọ̀ nígbà tí o bá di aṣẹ́gun àwa yóò gbé àsíá wa sókè ní orúkọ Ọlọ́run wa. Kí Olúwa kí ó mú gbogbo ìbéèrè rẹ̀ ṣẹ.
Rĩrĩa ũkaahootana nĩtũkoigĩrĩria na gĩkeno, na tuoye bendera ciitũ na igũrũ nĩ ũndũ wa rĩĩtwa rĩa Ngai witũ. Jehova arokũhingĩria maũndũ marĩa mothe ũmũhooete.
6 Nísinsin yìí, èmi mọ̀ wí pé, Olúwa pa ẹni àmì òróró rẹ̀ mọ́. Yóò gbọ́ láti ọ̀run mímọ́ rẹ̀ wá pẹ̀lú agbára ìgbàlà ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀.
Rĩu nĩmenyete atĩ Jehova nĩahonokagia ũrĩa wake mũitĩrĩrie maguta; nĩamwĩtĩkaga arĩ kũu igũrũ rĩake rĩamũre, arĩ na ũhoti wa kũhonokania ũrĩa ũrĩ guoko-inĩ gwake kwa ũrĩo.
7 Àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé kẹ̀kẹ́, àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé ẹṣin, ṣùgbọ́n àwa gbẹ́kẹ̀lé orúkọ Olúwa Ọlọ́run wa.
Andũ amwe mehokaga ngaari cia ita, na angĩ makehoka mbarathi, no ithuĩ twĩhokaga rĩĩtwa rĩa Jehova Ngai witũ.
8 Wọ́n wólẹ̀, ní eékún, wọ́n sì ṣubú, ṣùgbọ́n àwa dìde, a sì dúró ṣinṣin.
Makurumaga makagũa thĩ, no ithuĩ tũrũgamaga tũkehaanda.
9 Olúwa, fi ìṣẹ́gun fún ọba! Dá wa lóhùn nígbà tí a bá ń kígbe pè!
Wee Jehova, honokia mũthamaki! Twĩtĩkage rĩrĩa twagũkaĩra!