< Psalms 20 >

1 Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Kí Olúwa kí ó gbóhùn rẹ ní ọjọ́ ìpọ́njú; kí orúkọ Ọlọ́run Jakọbu kí ó dáàbò bò ọ́.
Se nabasu da dima doaga: sea, Hina Gode da di fidimu da defea. Ya: igobe ea Gode da di gaga: mu da defea.
2 Kí ó rán ìrànlọ́wọ́ sí ọ, láti ibi mímọ́ kí ó sì tì ọ́ lẹ́yìn láti Sioni wá.
E da Ea Debolo diasuga dima fidisu iasimu amola Saione Goumia dima fidisu iasimu da defea.
3 Kí ó sì rántí gbogbo ẹbọ rẹ kí ó sì gba ẹbọ sísun rẹ. (Sela)
E da dia hahawane dogolegele iasu huluane lamu da defea. E da dia gobele salasu huluane hahawane ba: mu da defea.
4 Kí ó fi fún ọ gẹ́gẹ́ bi ti èrò ọkàn rẹ kí ó sì mú gbogbo ìmọ̀ rẹ ṣẹ.
E da dia hanai huluane dima imunu amola dia fa: no hamomu sia: hahamoi amo huluane didima: ne hamomu da defea.
5 Àwa yóò hó fún ayọ̀ nígbà tí o bá di aṣẹ́gun àwa yóò gbé àsíá wa sókè ní orúkọ Ọlọ́run wa. Kí Olúwa kí ó mú gbogbo ìbéèrè rẹ̀ ṣẹ.
Amasea, di da hasalasi dagoi ba: sea, ninia da hahawane bagade wele sia: mu. Amola dia hasalasi dawa: ma: ne, Godema bagadewane nodomu. Gode da dia adole ba: su huluane amo defele adole imunu da defea.
6 Nísinsin yìí, èmi mọ̀ wí pé, Olúwa pa ẹni àmì òróró rẹ̀ mọ́. Yóò gbọ́ láti ọ̀run mímọ́ rẹ̀ wá pẹ̀lú agbára ìgbàlà ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀.
Na da wali dawa: , Hina Gode da Ea ilegei hina bagade ema hasalasu hou iaha. E da Ea hadigi Hebene soge amoga hina bagadema adole iaha amola Ea gasaga ema hasalasu hou bagade iaha.
7 Àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé kẹ̀kẹ́, àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé ẹṣin, ṣùgbọ́n àwa gbẹ́kẹ̀lé orúkọ Olúwa Ọlọ́run wa.
Dunu mogili da ilia gegesu sa: liode amoga ilia ha lai amoga hasalasimusa: dawa: lala. Mogili da gegesu hosi, bagohame gaguiba: le, hasalasimusa: dawa: Be ninia da ninia Hina Gode Ea gasa bagade dafawaneyale dawa: beba: le fawane, hasalasimusa: dawa:
8 Wọ́n wólẹ̀, ní eékún, wọ́n sì ṣubú, ṣùgbọ́n àwa dìde, a sì dúró ṣinṣin.
Dunu mogili da didigabone dafamu. Be ninia da wa: legadole, gasawane lelumu.
9 Olúwa, fi ìṣẹ́gun fún ọba! Dá wa lóhùn nígbà tí a bá ń kígbe pè!
Hina Gode! Di da hina bagade ema hasalasu hou ima. Ninia wele adole ba: su amoma Dia dabe adole ima.

< Psalms 20 >