< Psalms 19 >

1 Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Àwọn ọ̀run ń sọ nípa ti ògo Ọlọ́run; àwọsánmọ̀ ń sọ nípa ti iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.
Katoeng kruek zaehoikung hanah, David ih saam laa. Vannnawk mah Sithaw lensawkhaih to taphong o, long ranui ih van mah a toksakhaih to amtuengsak.
2 Wọ́n ń fọhùn ní ọjọ́ dé ọjọ́; wọ́n ń fi ìmọ̀ hàn ní alẹ́ dé alẹ́.
Nito pacoeng nito lokthuih o moe, qumto pacoeng qumto palunghahaih to amtueng o sak.
3 Kò sí ohùn tàbí èdè níbi tí a kò gbé gbọ́ ìró wọn.
Lokthuihaih hoi lokpaehhaih to om ai; kawbaktih ahmuen ah doeh nihcae ih lok thaih han om ai.
4 Ohùn wọn jáde lọ sí gbogbo orílẹ̀ ayé, ọ̀rọ̀ wọn títí dé òpin ilẹ̀ ayé. Ó ti kọ́ àgọ́ fún oòrùn nínú àwọn ọ̀run.
Toe nihcae ih lok loe longpum ah phak, a loknawk loe long boenghaih khoek to amthang boeh. Van ah ni ohhaih kahni im to a sak pae,
5 Tí ó dàbí ọkọ ìyàwó tí ó ń jáde ti yàrá rẹ̀ wá, òun yọ bí alágbára ọkùnrin tí ó ń sáré ìje.
ni loe impui thung hoi tacawt zu la thendoeng baktiah oh, angnoekhaih ahmuen ah anghoehaih hoi kacawn thacak kami hoiah anghmong.
6 Ìjáde lọ rẹ̀ ni láti òpin ọ̀run wá àti àyíká rẹ̀ sì dé ìpínlẹ̀ rẹ̀; kò sì sí ohun tí ó pamọ́ kúrò nínú oore rẹ̀.
Anih loe van boenghaih hoiah tacawt moe, van boenghaih khoek to takui: ni aengh mah phak han ai ah kanghawk hmuen tidoeh om ai.
7 Pípé ni òfin Olúwa, ó ń yí ọkàn padà. Ẹ̀rí Olúwa dánilójú, ó sọ òpè di ọlọ́gbọ́n.
Angraeng ih kaalok loe acung moe, muithla to amkhraisak: Angraeng mah thuih ih lok loe oepthoh moe, palungha ai kaminawk to palunghasak.
8 Ìlànà Olúwa tọ̀nà, ó ń fi ayọ̀ fún ọkàn. Àṣẹ Olúwa ni mímọ́, ó ń fi ìmọ́lẹ̀ fún ojú.
Angraeng thuitaekhaih loknawk loe toeng moe, palungthin to anghoesak; Angraeng ih kaaloknawk loe ciim moe, mik to amtuengsak.
9 Ìbẹ̀rù Olúwa mọ́, ó ń faradà títí láéláé. Ìdájọ́ Olúwa dájú òdodo ni gbogbo wọn.
Angraeng zithaih loe ciim moe, dungzan khoek to cak poe: Angraeng lok takroekhaih loe amsoem moe, toeng boih.
10 Wọn ṣọ̀wọ́n ju wúrà lọ, ju wúrà tí o dára jùlọ, wọ́n dùn ju oyin lọ, àti ju afárá oyin lọ.
Sui pongah atho nat, ue, kaciim suitui pongah doeh koeh han oh kue: khoitui pongah luep moe, khoi lutui pongah doeh luep kue.
11 Nípa wọn ni a ti ṣí ìránṣẹ́ rẹ̀ létí; nípa pípa wọ́n mọ́, èrè púpọ̀ ń bẹ.
To baktih hmuennawk hoiah na tamnanawk to acoehaih na paek, daan pazuihaih loe paroeai kalen tangqum to oh.
12 Ta ni ó lè mọ àṣìṣe rẹ̀? Dáríjì mí nínú àṣìṣe mi tí ó pamọ́.
Mi maw a sakpazaehaih panoek thaih? Kamtueng ai sakpazaehaih thung hoiah kai na ciimsak ah.
13 Wẹ ìránṣẹ́ rẹ mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ àmọ̀ọ́n-mọ̀-dá; má ṣe jẹ kí wọn kí ó jẹ ọba lórí mi. Nígbà náà ní èmi yóò dúró ṣinṣin, èmi yóò sì ṣe aláìlẹ́bi kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ ńlá.
Na tamna mah zaehaih sak parui poe han ai ah na pakaa ah; to zaehaihnawk mah kai na uk hmah nasoe: to tiah ni katoeng ah ka om ueloe, kalen parai zaehaih thung hoiah ka loih tih.
14 Jẹ́ kí ọ̀rọ̀ ẹnu mi àti àṣàrò ọkàn mi kí ó jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà ní ojú rẹ, Ìwọ Olúwa àpáta mi, àti Olùdáǹdè mi.
Aw Angraeng, ka thacakhaih hoi kai akrangkung, ka pakha thung ih loknawk hoi palung thungah ka poek ih hmuennawk loe, na hmaa ah talawk han koi ah om nasoe.

< Psalms 19 >