< Psalms 17 >

1 Àdúrà ti Dafidi. Gbọ́, Olúwa, ẹ̀bẹ̀ òtítọ́ mi; fi etí sí igbe mi. Tẹ́tí sí àdúrà mi tí kò ti ètè ẹ̀tàn jáde.
E HOOLOHE mai i ka pono, e Iehova; E manao mai oe i ka'u ulono ana'ku; E maliu mai hoi kou pepeiao i ka'u pule, Mai loko ae o na lehelehe hookamani ole.
2 Kí ìdáláre mi wá láti ọ̀dọ̀ rẹ; kí ojú rẹ kí ó rí ohun tí ó tọ́.
Mai kou alo pono mai e puka mai ai ka olelo no'u; E nana mai kou mau maka i na mea ewaewa ole.
3 Ìwọ ti dán àyà mi wò, ìwọ sì bẹ̀ mí wò ní òru, o sì ti wádìí mi, ìwọ kì yóò rí ohunkóhun èmi ti pinnu pé, ẹnu mi kì yóò ṣẹ̀.
Ua hoao mai nei oe i ko'u naau; Ua ike mai nei oe ia'u i ka po; Ua hoao mai nei oe ia'u, aohe e loaa ia oe: Ua paa kuu manao aole e hoohala kuu waha.
4 Bí ó ṣe ti iṣẹ́ ènìyàn nípa ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ, èmi ti pa ara mi mọ́ kúrò ní ọ̀nà àwọn ìkà.
I na hana a kanaka, no ka olelo pono mai a kou mau lehelehe, Ua malama au ia'u iho i na aoao o ka mea e make ai.
5 Ìrìn mí ti jẹ mọ́ ọ̀nà rẹ; ẹsẹ̀ mi kì yóò yọ̀.
E hookupono mai oe i ko'u hele ana ma kou mau alanui, I ole ai ko'u mou kapuwai e pahee.
6 Èmi ké pè ọ́, Ọlọ́run, nítorí tí ìwọ yóò dá mi lóhùn dẹ etí rẹ sí mi kí o sì gbọ́ àdúrà mi.
Ua kahea aku au ia oe, no ka mea, e lohe mai no oe ia'u, e ke Akua; E haliu mai ia'u kou pepeiao, e lono mai i ka'u olelo.
7 Fi ìṣeun ìyanu ìfẹ́ ńlá rẹ hàn ìwọ tí ó fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ gba àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé ọ là lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá tí ó dìde sí wọn.
E hoike mai oe i kou lokomaikai kupaianaha, E ka mea nana ka poe hilinai e hoopakele me kou lima akau i ka poe i ku e mai.
8 Pa mí mọ́ bí ẹyin ojú rẹ; fi mí pamọ́ sí abẹ́ òjìji ìyẹ́ apá rẹ,
E malama mai oe ia'u e like me ke kii onohi o ka maka, E huna oe ia'u malalo ae o ka malu o kou mau eheu,
9 lọ́wọ́ àwọn ènìyàn búburú tí ń fóròó mi, kúrò ní ọwọ́ àwọn ọ̀tá apani tí ó yí mi ká.
Mai ke alo mai o ka poe hewa i hooluhi mai ai ia'u, O ko'u poe enemi e make ai i hoopuni mai ia'u.
10 Wọ́n pa ọkàn aláìláàánú wọn mọ́, wọ́n sì fi ẹnu wọn sọ̀rọ̀ ìgbéraga.
Ua puni lakou i ko lakou momona: Ua olelo haaheo lakou me ko lakou waha.
11 Wọ́n sì mú mi mọ́lẹ̀, wọ́n sì yí mi ká, pẹ̀lú ojú ìṣọ́ra láti ṣọ́ mi sílẹ̀.
Ua hoopuni iho nei lakou ia makou i ko makou hele ana, Ua haka ko lakou maka me ke kulou ana ma ka lepo;
12 Wọn dàbí i kìnnìún tí ebi ń pa fún ìjẹ, àní bí kìnnìún ńlá tí ó ń ba níbi ìkọ̀kọ̀.
Me he liona pololi la e kuko ana i kana pio. Me he liona opiopio la, e moemoe malu ana ma na wahi anoano.
13 Dìde, Olúwa, dojúkọ wọ́n, rẹ̀ wọ́n sílẹ̀; gbà mí sílẹ̀ lọ́wọ́ ẹni búburú nípa idà rẹ.
E ku ae, e Iehova, e hoolapuwale ia ia, e kiola oe ia ia ilalo: E hoopakele oe i ko'u uhane i ka mea ino, i kau pahikaua;
14 Olúwa, nípa ọwọ́ rẹ, gbà mí kúrò lọ́wọ́ irú àwọn ènìyàn bẹ́ẹ̀, kúrò lọ́wọ́ àwọn ènìyàn ayé yìí, tí èrè wọn wà nínú ayé yìí. Ìwọ ń pa ebi àwọn tí ìwọ fẹ́ràn lẹ́nu mọ́; àwọn ọmọ wọn sì ní ọ̀pọ̀lọpọ̀, wọ́n sì kó ọrọ̀ jọ fún àwọn ọmọ wọn.
I na kanaka, i ka lima on, e Iehova, I ka poe ma keia ao, i loaa ko lakou waiwai i keia ola ana, Ua hoopihaia mai e oe ko lakou opu me kou waiwai i hunaia: Ua maona ko lakou mau kamalii, A waiho no lakou i ke koena na ka lakou mau keiki hou.
15 Ṣùgbọ́n ní tèmi, èmi yóò máa wo ojú rẹ ní òdodo; nígbà tí èmi bá jí, èmi yóò ní ìtẹ́lọ́rùn nígbà tí èmi bá rí àwòrán rẹ.
A owau hoi la, e ike auanei au i kou maka me ka pono; Aia e ala hou au me kou ano, alaila au e maha io ai.

< Psalms 17 >