< Psalms 17 >
1 Àdúrà ti Dafidi. Gbọ́, Olúwa, ẹ̀bẹ̀ òtítọ́ mi; fi etí sí igbe mi. Tẹ́tí sí àdúrà mi tí kò ti ètè ẹ̀tàn jáde.
Ihooya rĩa Daudi Wee Jehova, ta igua gũthaithana gwakwa kwa ũthingu; thikĩrĩria gũkaya gwakwa. Tega gũtũ ũigue ihooya rĩakwa, tondũ rĩtiumanĩte na mĩromo ya maheeni.
2 Kí ìdáláre mi wá láti ọ̀dọ̀ rẹ; kí ojú rẹ kí ó rí ohun tí ó tọ́.
Ituĩro rĩakwa rĩa kĩhooto nĩrĩkiume kũrĩ wee; maitho maku nĩmakĩone o ũndũ ũrĩa wagĩrĩire.
3 Ìwọ ti dán àyà mi wò, ìwọ sì bẹ̀ mí wò ní òru, o sì ti wádìí mi, ìwọ kì yóò rí ohunkóhun èmi ti pinnu pé, ẹnu mi kì yóò ṣẹ̀.
O na ũngĩthuthuuria ngoro yakwa na ũnduĩrie ũtukũ, o na ũngĩngeria, ndũrĩ ũndũ mũũru ũngĩona; nĩnduĩte atĩ ndikehia na kanua gakwa.
4 Bí ó ṣe ti iṣẹ́ ènìyàn nípa ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ, èmi ti pa ara mi mọ́ kúrò ní ọ̀nà àwọn ìkà.
Ha ũhoro wa ciĩko cia andũ, na ũndũ wa uuge wa mĩromo yaku niĩ ndũũrĩte ndĩrigagĩrĩria njĩra cia andũ arĩa mendete haaro.
5 Ìrìn mí ti jẹ mọ́ ọ̀nà rẹ; ẹsẹ̀ mi kì yóò yọ̀.
Makinya makwa nĩmarũmĩtie njĩra ciaku; magũrũ makwa matirĩ matenderũka.
6 Èmi ké pè ọ́, Ọlọ́run, nítorí tí ìwọ yóò dá mi lóhùn dẹ etí rẹ sí mi kí o sì gbọ́ àdúrà mi.
Wee Mũrungu, ngũkayagĩra tondũ nĩũnjĩtĩkaga; ndegera gũtũ na ũigue ihooya rĩakwa.
7 Fi ìṣeun ìyanu ìfẹ́ ńlá rẹ hàn ìwọ tí ó fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ gba àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé ọ là lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá tí ó dìde sí wọn.
Tũma magegania ma wendo waku mũnene monekane, Wee ũhonokanagia na guoko gwaku kwa ũrĩo arĩa moragĩra harĩwe kuuma kũrĩ thũ ciao.
8 Pa mí mọ́ bí ẹyin ojú rẹ; fi mí pamọ́ sí abẹ́ òjìji ìyẹ́ apá rẹ,
Menyagĩrĩra niĩ ta kĩũma kĩa riitho rĩaku; hitha kĩĩruru-inĩ kĩa mathagu maku
9 lọ́wọ́ àwọn ènìyàn búburú tí ń fóròó mi, kúrò ní ọwọ́ àwọn ọ̀tá apani tí ó yí mi ká.
ndigakorwo nĩ andũ arĩa aaganu arĩa maatharĩkagĩra, na kuuma kũrĩ thũ cia muoyo wakwa iria cindigiicĩirie.
10 Wọ́n pa ọkàn aláìláàánú wọn mọ́, wọ́n sì fi ẹnu wọn sọ̀rọ̀ ìgbéraga.
Nĩmahinganĩtie ngoro ciao nyũmũ, na tuo tũnua twao tũkaaria na mwĩgaatho.
11 Wọ́n sì mú mi mọ́lẹ̀, wọ́n sì yí mi ká, pẹ̀lú ojú ìṣọ́ra láti ṣọ́ mi sílẹ̀.
Maahĩtĩte, rĩu nĩmandigiicĩirie, mangũũrĩire maitho, mone mweke wa kũnũnda.
12 Wọn dàbí i kìnnìún tí ebi ń pa fún ìjẹ, àní bí kìnnìún ńlá tí ó ń ba níbi ìkọ̀kọ̀.
Mahaana ta mũrũũthi ũhũtĩire ndĩa yaguo, makahaana ta mũrũũthi mũnene woheirie kĩrĩa ũrenda kũnyiita.
13 Dìde, Olúwa, dojúkọ wọ́n, rẹ̀ wọ́n sílẹ̀; gbà mí sílẹ̀ lọ́wọ́ ẹni búburú nípa idà rẹ.
Arahũka, Wee Jehova, mangʼethere, ũmahoote; ndeithũra na rũhiũ rwaku rwa njora kuuma kũrĩ andũ arĩa aaganu.
14 Olúwa, nípa ọwọ́ rẹ, gbà mí kúrò lọ́wọ́ irú àwọn ènìyàn bẹ́ẹ̀, kúrò lọ́wọ́ àwọn ènìyàn ayé yìí, tí èrè wọn wà nínú ayé yìí. Ìwọ ń pa ebi àwọn tí ìwọ fẹ́ràn lẹ́nu mọ́; àwọn ọmọ wọn sì ní ọ̀pọ̀lọpọ̀, wọ́n sì kó ọrọ̀ jọ fún àwọn ọmọ wọn.
Wee Jehova, honokia na guoko gwaku kuuma kũrĩ andũ ta acio, ũũhonokie kuuma kũrĩ andũ a thĩ ĩno arĩa irĩhi rĩao rĩrĩ o muoyo-inĩ ũyũ tũrĩ. Ũniinagĩra andũ arĩa wendete ngʼaragu ũkamahũũnia; ciana ciao irĩ na cia kũigana, na nĩmaigagĩra ciana cia ciana ciao mũthiithũ.
15 Ṣùgbọ́n ní tèmi, èmi yóò máa wo ojú rẹ ní òdodo; nígbà tí èmi bá jí, èmi yóò ní ìtẹ́lọ́rùn nígbà tí èmi bá rí àwòrán rẹ.
Na niĩ-rĩ, nĩngeyonera ũthiũ waku na ũthingu; rĩrĩa ngokĩra-rĩ, nĩngaĩiganwo nĩgũkuona ũrĩa ũtariĩ.