< Psalms 16 >
1 Miktamu ti Dafidi. Pa mí mọ́, Ọlọ́run, nítorí nínú rẹ ni ààbò mi wà.
Złota pieśń Dawidowa.
2 Mo sọ fún Olúwa, “Ìwọ ni Olúwa mi, lẹ́yìn rẹ èmi kò ní ìre kan.”
Strzeż mię, o Boże! bo w tobie ufam. Rzecz, duszo moja! Panu: Tyś Pan mój, a dobroć moja nic ci nie pomoże,
3 Sí àwọn ènìyàn tí ó wà ní ayé, àwọn ni ológo nínú èyí tí ayọ̀ mí wà.
Ale świętym, którzy są na ziemi, i zacnym, w których wszystko kochanie moje.
4 Ìṣòro àwọn wọ̀n-ọn-nì yóò pọ̀ sí i, àní àwọn tí ń tọ ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn. Ẹbọ ohun mímu ẹ̀jẹ̀ wọn ni èmi kì yóò ta sílẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò dá orúkọ wọn lẹ́nu mi.
Rozmnożą się boleści tych, którzy się za cudzym bogiem kwapią; nie ukuszę ze krwi mokrych ofiar ich, ani wezmę imion ich w usta moje.
5 Olúwa, ni ìpín ìní mi tí mo yàn àti ago mi, ó ti pa ohun tí í ṣe tèmi mọ́.
Pan jest cząstką dziedzictwa mego, i kielicha mego, ty zatrzymujesz los mój.
6 Okùn ààlà ilẹ̀ ti bọ́ sí ọ̀dọ̀ mi ní ibi dídára; nítòótọ́ mo ti ní ogún rere.
Sznury mi przypadły na miejscach wesołych, a dziedzictwo wdzięczne przyszło na mię.
7 Èmi yóò yin Olúwa, ẹni tí ó gbà mí ní ìyànjú; ní òru, ọkàn mí ń bá mi sọ̀rọ̀.
Będę błogosławił Pana, który mi dał radę, gdyż i w nocy ćwiczą mię nerki moje.
8 Mo ti gbé Olúwa síwájú mi ní ìgbà gbogbo. Nítorí tí ó wà ní ọwọ́ ọ̀tún mi, a kì yóò mì mí.
Stawiałem Pana zawsze przed oczyma swemi; a iż on jest po prawicy mojej, nie będę wzruszony.
9 Nítorí èyí, ọkàn mi yọ̀, ahọ́n mi pẹ̀lú ń fò fáyọ̀; ara mi pẹ̀lú yóò sinmi ní ààbò,
Przetoż uweseliło się serce moje, a rozradowała się chwała moja; dotego ciało moje mieszkać będzie bezpiecznie.
10 nítorí ìwọ kò ní fi ọ̀kan sílẹ̀ nínú isà òkú, tàbí kí ìwọ jẹ́ kí ẹni mímọ́ rẹ kí ó rí ìdíbàjẹ́. (Sheol )
Bo nie zostawisz duszy mojej w grobie, ani dopuścisz świętemu twemu oglądać skażenia. (Sheol )
11 Ìwọ ti fi ipa ọ̀nà ìyè hàn mí; Ìwọ yóò kún mi pẹ̀lú ayọ̀ ní iwájú rẹ, pẹ̀lú ìdùnnú ayérayé ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ.
Oznajmisz mi drogę żywota; obfitość wesela jest przed obliczem twojem, rozkoszy po prawicy twojej aż na wieki.