< Psalms 16 >

1 Miktamu ti Dafidi. Pa mí mọ́, Ọlọ́run, nítorí nínú rẹ ni ààbò mi wà.
MAING Kot, kom kotin sinsila ia, pwe i liki komui.
2 Mo sọ fún Olúwa, “Ìwọ ni Olúwa mi, lẹ́yìn rẹ èmi kò ní ìre kan.”
Ngai potoan ong Ieowa: Komui ta ai Kaun, sota eu pai, me i asa, pwe komui eta.
3 Sí àwọn ènìyàn tí ó wà ní ayé, àwọn ni ológo nínú èyí tí ayọ̀ mí wà.
O I kin indang saraui kan, me kin mi nan sappa: Met akan pwin isou, me I kin pokepoke sang ni mongiong i.
4 Ìṣòro àwọn wọ̀n-ọn-nì yóò pọ̀ sí i, àní àwọn tí ń tọ ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn. Ẹbọ ohun mímu ẹ̀jẹ̀ wọn ni èmi kì yóò ta sílẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò dá orúkọ wọn lẹ́nu mi.
A irail me kin idedauen amen, pan lodi ong apwal toto. I sota mauki arail mairong, me doleki nta, de mar arail I sota pan inda.
5 Olúwa, ni ìpín ìní mi tí mo yàn àti ago mi, ó ti pa ohun tí í ṣe tèmi mọ́.
A Ieowa ai pai o ai peren; Komui kin kolekol ai soso.
6 Okùn ààlà ilẹ̀ ti bọ́ sí ọ̀dọ̀ mi ní ibi dídára; nítòótọ́ mo ti ní ogún rere.
I diaradar ai pwais en sap kaselel eu, ei pai kaselel eu, me i sosokier.
7 Èmi yóò yin Olúwa, ẹni tí ó gbà mí ní ìyànjú; ní òru, ọkàn mí ń bá mi sọ̀rọ̀.
I kapinga Ieowa, me kotin kalolekong ia; pil ni pong mudilik i kan kin padaki ong ia.
8 Mo ti gbé Olúwa síwájú mi ní ìgbà gbogbo. Nítorí tí ó wà ní ọwọ́ ọ̀tún mi, a kì yóò mì mí.
I kin ariri Ieowa ansau karos, pwe a kotikot ni pali maun i, i ap sota pan luetala.
9 Nítorí èyí, ọkàn mi yọ̀, ahọ́n mi pẹ̀lú ń fò fáyọ̀; ara mi pẹ̀lú yóò sinmi ní ààbò,
I me mongiong i kin peren kida, o ngen i kin popol, pwe pil pali uduk ai pan moleilei.
10 nítorí ìwọ kò ní fi ọ̀kan sílẹ̀ nínú isà òkú, tàbí kí ìwọ jẹ́ kí ẹni mímọ́ rẹ kí ó rí ìdíbàjẹ́. (Sheol h7585)
Pwe kom sota pan kotin mauki, ngen i en mimieta nan wasan mela, o kom sota pan mueid ong, me sapwilim omui saraui men pan mor pasang. (Sheol h7585)
11 Ìwọ ti fi ipa ọ̀nà ìyè hàn mí; Ìwọ yóò kún mi pẹ̀lú ayọ̀ ní iwájú rẹ, pẹ̀lú ìdùnnú ayérayé ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ.
Kom kin kotin kaasa kin ia al maur; peren lapalap mi mon silang omui, o meid lingan ni pali maun en lim omui kokolata.

< Psalms 16 >