< Psalms 15 >
1 Saamu ti Dafidi. Olúwa, ta ni yóò máa ṣe àtìpó nínú àgọ́ rẹ? Ta ni yóò máa gbé ní òkè mímọ́ rẹ?
Un psalm al lui David. DOAMNE, cine va sta în tabernacolul tău? Cine va locui pe muntele tău sfânt?
2 Ẹni tí ń rìn déédé tí ó sì ń sọ òtítọ́, láti inú ọkàn rẹ̀;
Cel ce umblă cu integritate și lucrează dreptate și vorbește adevărul în inima sa.
3 tí kò fi ahọ́n rẹ̀ sọ̀rọ̀ ẹni lẹ́yìn, tí kò ṣe ibi sí aládùúgbò rẹ̀ tí kò sì sọ̀rọ̀ ẹ̀gàn sí ẹnìkejì rẹ̀,
Cel ce nu defăimează cu limba sa, nici nu face rău aproapelui său, nici nu aduce ocară asupra aproapelui său.
4 ní ojú ẹni tí ènìyànkénìyàn di gígàn ṣùgbọ́n ó bọ̀wọ̀ fún àwọn tí ó bẹ̀rù Olúwa, ẹni tí ó búra sí ibi ara rẹ̀ àní tí kò sì yípadà,
În ochii lui un nemernic este disprețuit, dar onorează pe cei ce se tem de DOMNUL. Cel ce jură spre propria lui vătămare și nu schimbă jurământul.
5 tí ó ń yá ni lówó láìsí èlé tí kò sì gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lòdì sí aláìlẹ́ṣẹ̀. Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe èyí ni a kì yóò mì láéláé.
Cel ce nu își dă banii cu camătă, nici nu ia mită împotriva celui nevinovat. Cel ce face acestea nu se va clătina niciodată.