< Psalms 15 >

1 Saamu ti Dafidi. Olúwa, ta ni yóò máa ṣe àtìpó nínú àgọ́ rẹ? Ta ni yóò máa gbé ní òkè mímọ́ rẹ?
Pieśń Dawidowa. Panie! któż będzie przebywał w przybytku twoim? Któż będzie mieszkał na świętej górze twojej?
2 Ẹni tí ń rìn déédé tí ó sì ń sọ òtítọ́, láti inú ọkàn rẹ̀;
Ten, który chodzi w niewinności, i czyni sprawiedliwość, a mówi prawdę w sercu swojem;
3 tí kò fi ahọ́n rẹ̀ sọ̀rọ̀ ẹni lẹ́yìn, tí kò ṣe ibi sí aládùúgbò rẹ̀ tí kò sì sọ̀rọ̀ ẹ̀gàn sí ẹnìkejì rẹ̀,
Który nie obmawia językiem swoim, nic złego nie czyni bliźniemu swemu, ani zelżywości kładzie na bliźniego swego.
4 ní ojú ẹni tí ènìyànkénìyàn di gígàn ṣùgbọ́n ó bọ̀wọ̀ fún àwọn tí ó bẹ̀rù Olúwa, ẹni tí ó búra sí ibi ara rẹ̀ àní tí kò sì yípadà,
Przed którego oczyma wzgardzony jest niezbożnik, ale tych, którzy się boją Pana, ma w uczciwości; który, choć przysięże z szkodą swoją, nie odmienia;
5 tí ó ń yá ni lówó láìsí èlé tí kò sì gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lòdì sí aláìlẹ́ṣẹ̀. Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe èyí ni a kì yóò mì láéláé.
Który pieniędzy swych nie daje na lichwę, i darów przeciwko niewinnym nie przyjmuje. Kto to czyni, nie zachwieje się na wieki.

< Psalms 15 >