< Psalms 149 >

1 Ẹ fi ìyìn fún Olúwa. Ẹ kọrin tuntun sí Olúwa. Ẹ yìn ín ní àwùjọ àwọn ènìyàn mímọ́.
Ⱨǝmdusana! Pǝrwǝrdigarƣa atap yengi bir nahxini oⱪunglar; Mɵmin bǝndilǝrning jamaitidǝ Uning mǝdⱨiyisini eytinglar!
2 Jẹ́ kí Israẹli kí ó ní inú dídùn sí ẹni tí ó dá a jẹ́ kí àwọn ọmọ Sioni kí ó ní ayọ̀ nínú ọba wọn.
Israil ɵz Yaratⱪuqisidin xadlansun; Zion oƣulliri ɵz Padixaⱨidin hux bolƣay!
3 Jẹ́ kí wọn kí ó fi ijó yin orúkọ rẹ̀ jẹ́ kí wọn kí ó fi ohun èlò orin kọrin ìyìn sí i.
Ular Uning namini ussul bilǝn mǝdⱨiyilisun; Uningƣa küylǝrni dap ⱨǝm qiltarƣa tǝngxǝp eytsun!
4 Nítorí Olúwa ní inú dídùn sí àwọn ènìyàn rẹ̀ ó fi ìgbàlà dé àwọn onírẹ̀lẹ̀ ládé.
Qünki Pǝrwǝrdigar Ɵz hǝlⱪidin sɵyünǝr; U yawax mɵminlǝrni nijatliⱪ bilǝn bezǝydu;
5 Jẹ́ kí àwọn ènìyàn mímọ́ kí ó yọ̀ nínú ọlá rẹ̀ kí wọn kí ó máa kọrin fún ayọ̀ ní orí ibùsùn wọn.
Uning mɵmin bǝndiliri xan-xǝrǝptǝ roⱨlinip xad bolƣay, Orunlirida yetip xad awazini yangratⱪay!
6 Kí ìyìn Ọlọ́run kí ó wà ní ẹnu wọn àti idà olójú méjì ní ọwọ́ wọn.
Aƣzida Tǝngrigǝ yüksǝk mǝdⱨiyiliri bolsun, Ⱪollirida ⱪox bisliⱪ ⱪiliq tutulsun;
7 Láti gba ẹ̀san lára àwọn orílẹ̀-èdè, àti ìjìyà lára àwọn ènìyàn,
Xuning bilǝn ular ǝllǝr üstidin ⱪisas, Hǝlⱪlǝrgǝ jaza bǝja yürgüzidu;
8 láti fi ẹ̀wọ̀n de àwọn ọba wọn àti láti fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ irin de àwọn ọlọ́lá wọn.
Əllǝrning padixaⱨlirini zǝnjirlǝr bilǝn, Aⱪsɵngǝklirini tɵmür kixǝnliri bilǝn baƣlaydu;
9 Láti ṣe ìdájọ́ tí àkọsílẹ̀ rẹ̀ sí wọn èyí ni ògo àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀. Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.
Ularning üstigǝ pütülgǝn ⱨɵkümni bǝja kǝltüridu — Uning barliⱪ mɵmin bǝndiliri muxu xǝrǝpkǝ nesip bolidu! Ⱨǝmdusana!

< Psalms 149 >