< Psalms 149 >

1 Ẹ fi ìyìn fún Olúwa. Ẹ kọrin tuntun sí Olúwa. Ẹ yìn ín ní àwùjọ àwọn ènìyàn mímọ́.
Angraeng to saphaw oh. Angraeng khaeah laa kangtha to sah oh, kaciim kaminawk amkhuenghaih ahmuen ah anih saphawhaih laa to sah oh.
2 Jẹ́ kí Israẹli kí ó ní inú dídùn sí ẹni tí ó dá a jẹ́ kí àwọn ọmọ Sioni kí ó ní ayọ̀ nínú ọba wọn.
Israel loe anih sahkung nuiah anghoe nasoe; Zion caanawk loe angmacae siangpahrang nuiah anghoe o nasoe.
3 Jẹ́ kí wọn kí ó fi ijó yin orúkọ rẹ̀ jẹ́ kí wọn kí ó fi ohun èlò orin kọrin ìyìn sí i.
Anih ih ahmin to hnawhaih hoiah saphaw o nasoe; satuem hoi katoeng hoiah anih saphawhaih laa to sah o nasoe.
4 Nítorí Olúwa ní inú dídùn sí àwọn ènìyàn rẹ̀ ó fi ìgbàlà dé àwọn onírẹ̀lẹ̀ ládé.
Angraeng loe angmah ih kaminawk nuiah anghoehaih tawnh; kami tlim ah khosah kaminawk loe pahlonghaih hoiah amthoepsak tih.
5 Jẹ́ kí àwọn ènìyàn mímọ́ kí ó yọ̀ nínú ọlá rẹ̀ kí wọn kí ó máa kọrin fún ayọ̀ ní orí ibùsùn wọn.
Kaciim kaminawk loe lensawkhaih hoiah anghoe o nasoe; a iih o haih ahmuen hoiah anghoehaih laa to sah o nasoe.
6 Kí ìyìn Ọlọ́run kí ó wà ní ẹnu wọn àti idà olójú méjì ní ọwọ́ wọn.
Nihcae ih pakha ah Kasang koek Sithaw saphawhaih to om nasoe; nihcae ban ah ahnuk ahma kanoe sumsen to om nasoe,
7 Láti gba ẹ̀san lára àwọn orílẹ̀-èdè, àti ìjìyà lára àwọn ènìyàn,
Sithaw panoek ai kaminawk nuiah lu la ah loe, kaminawk to danpaek ah;
8 láti fi ẹ̀wọ̀n de àwọn ọba wọn àti láti fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ irin de àwọn ọlọ́lá wọn.
nihcae siangpahrangnawk to qui hoiah taoengh loe, nihcae ih lensawk kaminawk doeh sumboeng hoiah thlongthuk ah:
9 Láti ṣe ìdájọ́ tí àkọsílẹ̀ rẹ̀ sí wọn èyí ni ògo àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀. Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.
cabu thungah tarik ih baktih toengah, nihcae to kating ah lokcaek ah: hae loe kaciim Angmah ih kaminawk boih mah hak han koi pazawkhaih ah oh. Angraeng to saphaw oh.

< Psalms 149 >