< Psalms 147 >

1 Ẹ fi ìyìn fún Olúwa. Nítorí ohun rere ni láti máa kọrin ìyìn sí Ọlọ́run wa, ó yẹ láti kọrin ìyìn sí i!
BOEIPA te thangthen uh. Mamih kah Pathen tingtoeng he then tih koehnah neh naepnoi rhoeprhui pai.
2 Olúwa kọ́ Jerusalẹmu; Ó kó àwọn Israẹli tí a lé sọnù jọ.
Jerusalem aka thoh BOEIPA loh a heh tih Israel te a calui.
3 Ó wo àwọn tí ọkàn wọ́n bàjẹ́ sàn ó sì di ọgbẹ́ wọ́n.
Lungbuei a rhek rhoek te a hoeih sak tih a hma te a poi pah.
4 Ó ka iye àwọn ìràwọ̀ ó sì pe ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn ní orúkọ.
Aisi rhoek ke amah tarhing la a tae tih a ming te rhip a sui.
5 Títóbi ni Olúwa wa ó sì pọ̀ ní agbára òye rẹ̀ kò sì ní òpin.
Mamih kah Boeipa tah len tih a thadueng khaw yet. A lungcuei te tae lek pawh.
6 Olúwa wa pẹ̀lú àwọn onírẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni ó rẹ̀ àwọn ènìyàn búburú sílẹ̀.
Kodo rhoek aka tungaep BOEIPA loh halang rhoek te diklai la a kunyun sak.
7 Fi ọpẹ́ kọrin sí Olúwa fi ohun èlò orin olókùn yin Ọlọ́run.
BOEIPA te uemonah neh doo lamtah mamih kah Pathen te rhotoeng neh tingtoeng uh.
8 Ó fi ìkùùkuu bo àwọ̀ sánmọ̀ ó rọ òjò sí orílẹ̀ ayé ó mú kí koríko hù lórí àwọn òkè
Vaan ke khomai neh a thing tih diklai ham khotlan a hmoel pah dongah tlang ah sulrham a poe sak.
9 Ó pèsè oúnjẹ fún àwọn ẹranko àti fún àwọn ọmọ ẹyẹ ìwò ní ìgbà tí wọ́n bá ń ké.
A pang uh vaengah rhamsa ham neh vangak ca ham a buh a khueh pah.
10 Òun kò ní inú dídùn nínú agbára ẹṣin, bẹ́ẹ̀ ni Òun kò ní ayọ̀ sí ẹ̀ṣẹ̀ ọkùnrin
Marhang kah thayung thamal neh aka hmae pawt tih, hlang kho dongah khaw aka ngaingaih pawh.
11 Olúwa ni ayọ̀ nínú àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀, sí àwọn tí ó ní ìrètí nínú àánú rẹ̀.
Amah aka rhih so neh a sitlohnah dongah aka ngaiuep ni BOEIPA loh a ngaingaih.
12 Yin Olúwa, ìwọ Jerusalẹmu; yin Ọlọ́run rẹ, ìwọ Sioni.
Aw Jerusalem BOEIPA taengah domyok ti lamtah, aw Zion na Pathen te thangthen laeh.
13 Nítorí tí ó ti mú ọ̀pá ìdábùú ibodè rẹ̀ lágbára, Òun sì ti bùkún fún àwọn ọmọ rẹ̀ nínú rẹ
Na vongka kah thohkalh te a caang sak tih na kotak kah na ca rhoek te yoethen a paek.
14 Òun jẹ́ kí àlàáfíà wà ní àwọn ẹnu ibodè rẹ̀, òun sì fi jéró dáradára tẹ́ ọ lọ́rùn.
Na khorhi ah rhoepnah a khueh tih cang tha te nang n'kum sak.
15 Òun sì rán àṣẹ rẹ̀ sí ayé ọ̀rọ̀ rẹ̀ sáré tete.
A olthui te diklai la a tueih tih a ol loh leklek yong.
16 Ó fi yìnyín fún ni bi irun àgùntàn ó sì fọ́n ìrì dídì ká bí eérú
Vuelsong te tumul bangla a haeh tih vueltling te hmaiphu bangla a yaal.
17 Ó rọ òjò yìnyín rẹ̀ bí òkúta wẹ́wẹ́ ta ni ó lè dúró níwájú òtútù rẹ̀
A rhaelnu te a tham la a lun vaengah a khosik hmai ah unim aka pai thai?
18 Ó rán ọ̀rọ̀ rẹ̀ jáde ó sì mú wọn yọ̀ ó mú kí afẹ́fẹ́ rẹ̀ fẹ́ ó sì mú odò rẹ̀ sàn.
A ol a tueih vaengah te rhoek yut tih a hil neh a hmuh vaengah tui la cip.
19 Ó sọ ọ̀rọ̀ rẹ̀ di mí mọ̀ fún Jakọbu àwọn òfin àti ìlànà rẹ̀ fún Israẹli.
A ol te a ol bangla Jakob taengah, a oltlueh neh a laitloeknah Israel taengah a phoe sak.
20 Òun kó tí ṣe irú èyí sí orílẹ̀-èdè kan rí, bí ó ṣe ti ìdájọ́ rẹ̀ wọn ko mọ òfin rẹ̀. Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.
Te te namtom boeih taengah a saii pawt dongah ni laitloeknah te a ming uh pawh. BOEIPA te thangthen uh.

< Psalms 147 >