< Psalms 147 >

1 Ẹ fi ìyìn fún Olúwa. Nítorí ohun rere ni láti máa kọrin ìyìn sí Ọlọ́run wa, ó yẹ láti kọrin ìyìn sí i!
Dayega si Yahweh, kay maayo nga mag-awit sa mga pagdayeg sa atong Dios, maayo kini, ug angay ang pagdayeg.
2 Olúwa kọ́ Jerusalẹmu; Ó kó àwọn Israẹli tí a lé sọnù jọ.
Gitukod pag-usab ni Yahweh ang Jerusalem, gitigom niya ang mga nagkatibulaag nga katawhan sa Israel.
3 Ó wo àwọn tí ọkàn wọ́n bàjẹ́ sàn ó sì di ọgbẹ́ wọ́n.
Giayo niya ang nasakitan nga kasingkasing ug gibugkosan ang ilang mga samad.
4 Ó ka iye àwọn ìràwọ̀ ó sì pe ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn ní orúkọ.
Naihap niya ang mga bituon, ginganlan niya kining tanan.
5 Títóbi ni Olúwa wa ó sì pọ̀ ní agbára òye rẹ̀ kò sì ní òpin.
Bantogan ang atong Ginoo ug hilabihan kagamhanan, ang iyang panabot dili masukod.
6 Olúwa wa pẹ̀lú àwọn onírẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni ó rẹ̀ àwọn ènìyàn búburú sílẹ̀.
Gipataas ni Yahweh ang mga dinaogdaog, ug gipalukapa niya ang mga daotan ngadto sa yuta.
7 Fi ọpẹ́ kọrin sí Olúwa fi ohun èlò orin olókùn yin Ọlọ́run.
Awiti si Yahweh uban ang pagpasalamat, awiti ug mga pagdayeg ang atong Dios dinuyogan sa alpa.
8 Ó fi ìkùùkuu bo àwọ̀ sánmọ̀ ó rọ òjò sí orílẹ̀ ayé ó mú kí koríko hù lórí àwọn òkè
Gitabonan niya ang kalangitan sa mga panganod ug giandam ang ulan alang sa kalibotan, aron motubo ang sagbot sa kabukiran.
9 Ó pèsè oúnjẹ fún àwọn ẹranko àti fún àwọn ọmọ ẹyẹ ìwò ní ìgbà tí wọ́n bá ń ké.
Gihatagan niya ug mga pagkaon ang mga mananap ug ang mga pisu sa uwak sa dihang (sila) mopiyak.
10 Òun kò ní inú dídùn nínú agbára ẹṣin, bẹ́ẹ̀ ni Òun kò ní ayọ̀ sí ẹ̀ṣẹ̀ ọkùnrin
Wala siya makakaplag ug kalipay diha sa kusog sa kabayo, wala siya mahimuot sa kusgan nga mga paa sa tawo.
11 Olúwa ni ayọ̀ nínú àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀, sí àwọn tí ó ní ìrètí nínú àánú rẹ̀.
Mahimuot lamang si Yahweh niadtong magpasidungog kaniya, nga naglaom sa iyang matinud-anon nga kasabotan.
12 Yin Olúwa, ìwọ Jerusalẹmu; yin Ọlọ́run rẹ, ìwọ Sioni.
Dayega si Yahweh, Jerusalem, dayega ang imong Dios, Zion.
13 Nítorí tí ó ti mú ọ̀pá ìdábùú ibodè rẹ̀ lágbára, Òun sì ti bùkún fún àwọn ọmọ rẹ̀ nínú rẹ
Kay gipalig-on niya ang mga babag sa imong mga ganghaan, gipanalanginan niya ang imong mga anak taliwala kanimo.
14 Òun jẹ́ kí àlàáfíà wà ní àwọn ẹnu ibodè rẹ̀, òun sì fi jéró dáradára tẹ́ ọ lọ́rùn.
Magdala siya ug kauswagan sulod sa imong mga utlanan, tagbawon ka niya sa labing maayo nga trigo.
15 Òun sì rán àṣẹ rẹ̀ sí ayé ọ̀rọ̀ rẹ̀ sáré tete.
Gipadala niya ang iyang kasugoan ngadto sa kalibotan, ang iyang sugo moabot dayon.
16 Ó fi yìnyín fún ni bi irun àgùntàn ó sì fọ́n ìrì dídì ká bí eérú
Gihimo niya ang niyebe sama sa balahibo sa karnero, gikatag niya ang gagmay nga ice sama sa abo.
17 Ó rọ òjò yìnyín rẹ̀ bí òkúta wẹ́wẹ́ ta ni ó lè dúró níwájú òtútù rẹ̀
Nagpaulan siya ug ice sama sa dinugmok nga tinapay, kinsa man ang makaagwanta sa kabugnaw nga iyang gipadala?
18 Ó rán ọ̀rọ̀ rẹ̀ jáde ó sì mú wọn yọ̀ ó mú kí afẹ́fẹ́ rẹ̀ fẹ́ ó sì mú odò rẹ̀ sàn.
Gipadala niya ang iyang sugo ug nangalanay kini, gipahuros niya ang hangin ug gipadagayday ang tubig.
19 Ó sọ ọ̀rọ̀ rẹ̀ di mí mọ̀ fún Jakọbu àwọn òfin àti ìlànà rẹ̀ fún Israẹli.
Gimantala niya ang iyang pulong ngadto kang Jacob, ang iyang kabalaoran ug ang iyang matarong nga kasugoan sa Israel.
20 Òun kó tí ṣe irú èyí sí orílẹ̀-èdè kan rí, bí ó ṣe ti ìdájọ́ rẹ̀ wọn ko mọ òfin rẹ̀. Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.
Wala niya kini buhata sa uban nga nasod, ug mahitungod sa iyang kasugoan, wala (sila) masayod niini. Dayega si Yahweh.

< Psalms 147 >