< Psalms 147 >

1 Ẹ fi ìyìn fún Olúwa. Nítorí ohun rere ni láti máa kọrin ìyìn sí Ọlọ́run wa, ó yẹ láti kọrin ìyìn sí i!
Hina Godema nodoma! Ninia Godema nodone gesami hea: mu da defea! Ema nodomu da noga: idafa amola moloidafa.
2 Olúwa kọ́ Jerusalẹmu; Ó kó àwọn Israẹli tí a lé sọnù jọ.
Hina Gode da Yelusaleme ea hou bu hahamonana. E da mugululi asi dunu bu lale sala.
3 Ó wo àwọn tí ọkàn wọ́n bàjẹ́ sàn ó sì di ọgbẹ́ wọ́n.
E da baligili da: i dioi dunu amo ilia dogo denesisa. E da ilia fofa: gi lala: gisa.
4 Ó ka iye àwọn ìràwọ̀ ó sì pe ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn ní orúkọ.
E da gasumuni ilia idi ilegei dagoi. Amola gasumuni afae afae ilia dio adosa.
5 Títóbi ni Olúwa wa ó sì pọ̀ ní agbára òye rẹ̀ kò sì ní òpin.
Ninia Hina Gode da bagadedafa amola gasa bagadedafa. Ea asigi dawa: su amo afaega defemu da hamedei.
6 Olúwa wa pẹ̀lú àwọn onírẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni ó rẹ̀ àwọn ènìyàn búburú sílẹ̀.
E da fonoboi dunu wa: lesisa. Be wadela: i hamosu dunu, osoba banenesisa.
7 Fi ọpẹ́ kọrin sí Olúwa fi ohun èlò orin olókùn yin Ọlọ́run.
Hina Godema nodone gesami hea: ma! Ninia Godema nodone sani baidama duma!
8 Ó fi ìkùùkuu bo àwọ̀ sánmọ̀ ó rọ òjò sí orílẹ̀ ayé ó mú kí koríko hù lórí àwọn òkè
E da mu dedeboma: ne, mu mobi baila: lesisa. E da osobo bagadema gibu iaha. E da agologa, gisi heda: ma: ne hahamosa.
9 Ó pèsè oúnjẹ fún àwọn ẹranko àti fún àwọn ọmọ ẹyẹ ìwò ní ìgbà tí wọ́n bá ń ké.
E da ohe fi ilima ha: i manu iaha. Guimi mano da ga: sea, E da ilima ha: i manu iaha.
10 Òun kò ní inú dídùn nínú agbára ẹṣin, bẹ́ẹ̀ ni Òun kò ní ayọ̀ sí ẹ̀ṣẹ̀ ọkùnrin
E da gasa bagade hosi amola nimi bagade dadi gagui dunu amo hahawane hame ba: sa.
11 Olúwa ni ayọ̀ nínú àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀, sí àwọn tí ó ní ìrètí nínú àánú rẹ̀.
Be E da fonoboi dunu amo da Ema nodobe amola Ea mae fisili asigidafa hou dafawaneyale dawa: be, amo dunu E da hahawane ba: sa.
12 Yin Olúwa, ìwọ Jerusalẹmu; yin Ọlọ́run rẹ, ìwọ Sioni.
Yelusaleme fi! Hina Godema nodoma! Saione fi! Dilia Godema nodoma!
13 Nítorí tí ó ti mú ọ̀pá ìdábùú ibodè rẹ̀ lágbára, Òun sì ti bùkún fún àwọn ọmọ rẹ̀ nínú rẹ
E da dilia logo ga: su gasa bagadewane dialoma: ne hamosa. E da dilia fi dunuma hahawane hamosa.
14 Òun jẹ́ kí àlàáfíà wà ní àwọn ẹnu ibodè rẹ̀, òun sì fi jéró dáradára tẹ́ ọ lọ́rùn.
E da dilia soge alaloa gaga: sa. E da dili sadima: ne, widi ha: i manu noga: idafa dilima iaha.
15 Òun sì rán àṣẹ rẹ̀ sí ayé ọ̀rọ̀ rẹ̀ sáré tete.
E da osobo bagadema hamoma: ne sia: sea, Ea sia: be liligi da hedolowane hamoi dagoi ba: sa.
16 Ó fi yìnyín fún ni bi irun àgùntàn ó sì fọ́n ìrì dídì ká bí eérú
E da mugene su, abula agoai baila: lesisa. Amola anegagi ofo gulu agoane dudulisisa.
17 Ó rọ òjò yìnyín rẹ̀ bí òkúta wẹ́wẹ́ ta ni ó lè dúró níwájú òtútù rẹ̀
E da mugene amo igi fofonobo agoane iasisa. E da anegagidafa eso iasisia, dunu afae da amo ganodini esalumu hamedei ba: sa.
18 Ó rán ọ̀rọ̀ rẹ̀ jáde ó sì mú wọn yọ̀ ó mú kí afẹ́fẹ́ rẹ̀ fẹ́ ó sì mú odò rẹ̀ sàn.
Amasea, E da amo hamoma: ne sia: sea, mugene ganumu da daeasa. E da fo iasisia, hano da ahoana.
19 Ó sọ ọ̀rọ̀ rẹ̀ di mí mọ̀ fún Jakọbu àwọn òfin àti ìlànà rẹ̀ fún Israẹli.
E da sia: ne iasu amo Ea fi dunuma iaha. E da Ea sema amola hamoma: ne sia: i amo Isala: ili fi ilima iaha.
20 Òun kó tí ṣe irú èyí sí orílẹ̀-èdè kan rí, bí ó ṣe ti ìdájọ́ rẹ̀ wọn ko mọ òfin rẹ̀. Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.
E da eno fifi asi gala ilima agoane hame hamosu. Eno fifi asi gala, ilia da Ea sema hame dawa: Hina Godema nodoma!

< Psalms 147 >