< Psalms 144 >

1 Ti Dafidi. Ìyìn sí Olúwa àpáta mi, ẹni tí ó kọ́ ọwọ́ mi fún ogun, àti ìka mi fún ìjà.
Thaburi ya Daudi Jehova arogoocwo, o we Rwaro rwakwa rwa Ihiga, o we ũmenyithagia moko makwa mũrũĩre wa mbaara, agakĩruta ciara ciakwa kũrũa mbaara.
2 Òun ni Ọlọ́run ìfẹ́ mi àti odi alágbára mi, ibi gíga mi àti olùgbàlà mi, asà mi, ẹni tí èmi gbẹ́kẹ̀lé, ẹni tí ó tẹrí àwọn ènìyàn ba lábẹ́ mi.
Nĩwe Ngai ũrĩa ũnyendete, na nĩwe kĩirigo gĩakwa kĩa hinya, o we kĩĩhitho gĩakwa na mũhonokia wakwa, ningĩ nĩwe ngo yakwa, na nĩ harĩ we njũragĩra, o we ũtũmaga andũ a ndũrĩrĩ maathĩke marĩ rungu rwakwa.
3 Olúwa, kí ni ènìyàn tí ìwọ fi ń ṣàníyàn fún un, tàbí ọmọ ènìyàn tí ìwọ fi ń ronú nípa rẹ̀?
Wee Jehova, mũndũ akĩrĩ kĩ nĩguo ũmũmenyagĩrĩre, nake mũrũ wa mũndũ akĩrĩ kĩ nĩgeetha ũmũrũmbũyagie?
4 Ènìyàn rí bí èmi; ọjọ́ rẹ̀ rí bí òjìji tí ń kọjá lọ.
Mũndũ no ta mĩhũmũ; matukũ make mathiraga na ihenya o ta kĩĩruru.
5 Tẹ ọ̀run rẹ ba, Olúwa, kí o sì sọ̀kalẹ̀; tọ́ àwọn òkè ńlá wọn yóò sí rú èéfín.
Wee Jehova, hingũra igũrũ ũikũrũke; hutia irĩma, nĩgeetha irute ndogo.
6 Rán mọ̀nàmọ́ná kí ó sì fọ́n àwọn ọ̀tá ká; ta ọfà rẹ kí ó sì dà wọ́n rú.
Henũkia rũheni ũhurunje thũ ciaku; ikia mĩguĩ yaku ũcingatithie.
7 Na ọwọ́ rẹ sílẹ̀ láti ibi gíga; gbà mí kí o sì yọ mí nínú ewu kúrò nínú omi ńlá: kúrò lọ́wọ́ àwọn ọmọ àjèjì.
Tambũrũkia guoko gwaku ũrĩ igũrũ; ndeithũra na ũũthare kuuma kũrĩ maaĩ maya maingĩ, ũndute kuuma moko-inĩ ma andũ a kũngĩ
8 Ẹnu ẹni tí ó kún fún èké ẹni tí ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ jẹ́ ìrẹ́jẹ.
arĩa tũnua twao twaragia maheeni, o acio moko mao ma ũrĩo marĩ na wara.
9 Èmi yóò kọ orin tuntun sí ọ Ọlọ́run; lára ohun èlò orin olókùn mẹ́wàá èmi yóò kọ orin sí ọ.
Wee Ngai, nĩngũkũinĩra rwĩmbo rwerũ; ngũkũinĩra na kĩnanda kĩrĩa kĩgeetetwo na nga ikũmi,
10 Òun ni ó fi ìgbàlà fún àwọn ọba, ẹni tí ó gba Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ idà ìpanilára. Lọ́wọ́ pípanirun.
nyinĩre Ũrĩa ũhootanagĩra athamaki, o we ũhonokagia Daudi ndungata yake harĩ rũhiũ rwa njora rwa ũragani.
11 Gbà mí kí o sì yọ mí nínú ewu kúrò lọ́wọ́ àwọn ọmọ àjèjì tí ẹnu wọn kún fún èké, tí ọwọ́ ọ̀tún wọn jẹ́ ọwọ́ ọ̀tún èké.
Ndeithũra na ũũthare, ũndute kuuma moko-inĩ ma andũ a kũngĩ, arĩa tũnua twao twaragia maheeni, o acio moko mao ma ũrĩo marĩ ma wara.
12 Kí àwọn ọmọkùnrin wa kí ó dàbí igi gbígbìn tí ó dàgbà ni ìgbà èwe wọn, àti ọmọbìnrin wa yóò dàbí òpó ilé tí a ṣe ọ̀nà sí bí àfarawé ààfin.
Hĩndĩ ĩyo aanake aitũ magaatuĩka ta mĩmera mĩrore wega wĩthĩ-inĩ wao, nao airĩtu aitũ mahaane ta itugĩ ciacũhĩtio cia kũgemia nyũmba ya ũthamaki.
13 Àká wa yóò kún pẹ̀lú gbogbo onírúurú oúnjẹ àgùntàn wa yóò pọ̀ si ní ẹgbẹ̀rún, ní ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ní oko wa:
Makũmbĩ maitũ makaiyũragio irio cia mĩthemba yothe. Ngʼondu ciitũ ikaingĩha ikinye ngiri nyingĩ, cingĩhe ikinye makũmi ma ngiri kũu mĩgũnda-inĩ iitũ;
14 àwọn màlúù wa yóò ru ẹrù wúwo kí ó má sí ìkọlù, kí ó má sí ìkólọ sí ìgbèkùn, kí ó má sí i igbe ìpọ́njú ní ìgboro wa.
nacio ndegwa ciitũ nĩigakuuaga mĩrigo mĩritũ. Thingo itigakorwo na mĩanya, kana gũtahwo tũtwarwo ũkombo-inĩ, o na gũtigakorwo na kĩrĩro kĩa mĩnyamaro njĩra-inĩ cia matũũra.
15 Ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn náà tí ó wà ní irú ipò bẹ́ẹ̀, ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn náà, tí ẹni tí Ọlọ́run Olúwa ń ṣe.
Kũrathimwo nĩ andũ arĩa matariĩ ta ũguo; kũrathimwo nĩ andũ arĩa Ngai wao arĩ we Jehova.

< Psalms 144 >