< Psalms 144 >
1 Ti Dafidi. Ìyìn sí Olúwa àpáta mi, ẹni tí ó kọ́ ọwọ́ mi fún ogun, àti ìka mi fún ìjà.
Hina Gode da na Gaga: sudafa! Ema nodoma! E da na gegema: ne adoba: sa. Amola na gegema: ne momagesa.
2 Òun ni Ọlọ́run ìfẹ́ mi àti odi alágbára mi, ibi gíga mi àti olùgbàlà mi, asà mi, ẹni tí èmi gbẹ́kẹ̀lé, ẹni tí ó tẹrí àwọn ènìyàn ba lábẹ́ mi.
E da na gagulasa amola na gaga: sa. E da na ougiha aligisu dunu esala, amola na gaga: su dunu esala. Na da se mae nabawane hahawane masa: ne, Ea hou dafawaneyale dawa: sa. E da niha fifi asi gala banenesisa
3 Olúwa, kí ni ènìyàn tí ìwọ fi ń ṣàníyàn fún un, tàbí ọmọ ènìyàn tí ìwọ fi ń ronú nípa rẹ̀?
Hina Gode! Osobo bagade dunu ilia da hamedei agoai galebe. Dia abuliba: le ilima asigibala: ?
4 Ènìyàn rí bí èmi; ọjọ́ rẹ̀ rí bí òjìji tí ń kọjá lọ.
Ninia da fo fonomene agoai ba: sa. Ninia esalebe eso da baba bobaligilalebe agoai ba: sa.
5 Tẹ ọ̀run rẹ ba, Olúwa, kí o sì sọ̀kalẹ̀; tọ́ àwọn òkè ńlá wọn yóò sí rú èéfín.
Hina Gode! Mu gadelale fasili, gudu sa: ima! Goumi digili ba: ma! Amasea, goumi da mobi bubugilalebe ba: mu.
6 Rán mọ̀nàmọ́ná kí ó sì fọ́n àwọn ọ̀tá ká; ta ọfà rẹ kí ó sì dà wọ́n rú.
Dia ha lai afagogoma: ne, ha: ha: na gala: su iasima. Dia ha lai dunu hobeama: ne, dadia gala: le se bobogema.
7 Na ọwọ́ rẹ sílẹ̀ láti ibi gíga; gbà mí kí o sì yọ mí nínú ewu kúrò nínú omi ńlá: kúrò lọ́wọ́ àwọn ọmọ àjèjì.
Na da hano lugudua mogo sososa. Dia gadodili, lobo ligia guduli, na hiougia gadoma. Ga fi dunu ilia gasaga na hasalasa: besa: le, Dia gaga: ma.
8 Ẹnu ẹni tí ó kún fún èké ẹni tí ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ jẹ́ ìrẹ́jẹ.
Ilia da dafawane sia: hamedafa sia: sa. Amola ilia hamomusa: ilegele sia: sea, ogogosa.
9 Èmi yóò kọ orin tuntun sí ọ Ọlọ́run; lára ohun èlò orin olókùn mẹ́wàá èmi yóò kọ orin sí ọ.
Gode! Na da Dima gesami gaheabolo hea: mu. Na da sani baidama dusa, Dima gesami hea: mu.
10 Òun ni ó fi ìgbàlà fún àwọn ọba, ẹni tí ó gba Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ idà ìpanilára. Lọ́wọ́ pípanirun.
Di da hina bagade ilia ha lai hasalasima: ne hamosa. Amola Dia hawa: hamosu dunu Da: ibidi gaga: sa.
11 Gbà mí kí o sì yọ mí nínú ewu kúrò lọ́wọ́ àwọn ọmọ àjèjì tí ẹnu wọn kún fún èké, tí ọwọ́ ọ̀tún wọn jẹ́ ọwọ́ ọ̀tún èké.
Na dodona: gi ha lai dunu da na osa: la heda: sa: besa: le, Dia na gaga: ma. Ga fi dunu ilia gasaga na hasalasa: besa: le, Dia gaga: ma. Ilia da dafawane sia: hamedafa sia: sa. Amola ilia hamomusa: ilegele sia: sea, ogogosa.
12 Kí àwọn ọmọkùnrin wa kí ó dàbí igi gbígbìn tí ó dàgbà ni ìgbà èwe wọn, àti ọmọbìnrin wa yóò dàbí òpó ilé tí a ṣe ọ̀nà sí bí àfarawé ààfin.
Ninia dunu mano ayeligi amolali, da ha: i manu bugi nasegagini heda: be agoai ganumu da defea. Amola ninia idiwilali, ilia da noga: le lelu duni bugi amo da hina bagade ea diasu hegomaia nina: hamonanebe, amo agoai ba: mu da defea.
13 Àká wa yóò kún pẹ̀lú gbogbo onírúurú oúnjẹ àgùntàn wa yóò pọ̀ si ní ẹgbẹ̀rún, ní ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ní oko wa:
Ninia liligi legesu diasu ilia ha: i manu amoga nabai ba: mu da defea. Ninia sibi amo da nasegagi sogega esalebe, ilia mano osea: idafa lalelegemu da defea.
14 àwọn màlúù wa yóò ru ẹrù wúwo kí ó má sí ìkọlù, kí ó má sí ìkólọ sí ìgbèkùn, kí ó má sí i igbe ìpọ́njú ní ìgboro wa.
Ninia bulamagau da mae daba: me asili, mano osea: idafa lalelegemu da defea. Ninia moilai logo ganodini, se nabasu wele sia: su hame nabimu da defea.
15 Ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn náà tí ó wà ní irú ipò bẹ́ẹ̀, ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn náà, tí ẹni tí Ọlọ́run Olúwa ń ṣe.
Fifi asi afae da amo hou ba: sea, hahawane bagade ganumu. Amola ilia da Hina Gode amo ilia Godedafa ilegesea, ilia da hahawane bagade ganumu.