< Psalms 143 >

1 Saamu ti Dafidi. Olúwa gbọ́ àdúrà mi, fetísí igbe mi fún àánú; nínú òtítọ́ àti òdodo rẹ, wá fún ìrànlọ́wọ́ mi.
He himene na Rawiri. E Ihowa, whakarongo ki taku inoi, kia titaha mai tou taringa ki aku inoi: whakahokia mai he kupu ki ahau i runga i tou pono, i runga i tou tika.
2 Má ṣe mú ìránṣẹ́ rẹ wá sí ìdájọ́, nítorí kò sí ẹnìkan tí ó wà láààyè tí ó ṣe òdodo níwájú rẹ.
A kaua e anga e whakawa ki tau pononga: ki tau titiro hoki kahore tetahi mea ora e tika.
3 Ọ̀tá ń lépa mi, ó fún mi pamọ́ ilẹ̀; ó mú mi gbé nínú òkùnkùn bí àwọn tí ó ti kú ti pẹ́.
Kua tukinotia hoki toku wairua e te hoariri; patua iho e ia toku ora ki raro ki te whenua: meinga ana ahau e ia kia noho i nga wahi pouri, kia rite ki nga tupapaku onamata.
4 Nítorí náà ẹ̀mí mi ṣe rẹ̀wẹ̀sì nínú mi; ọkàn mi nínú mi ṣì pòruurù.
Na reira i ngaro ai toku wairua i roto i ahau: moti rawa toku ngakau i roto i ahau.
5 Èmi rántí ọjọ́ tí ó ti pẹ́; èmi ń ṣe àṣàrò lórí gbogbo iṣẹ́ rẹ mo sì ṣe àkíyèsí ohun tí ọwọ́ rẹ ti ṣe.
E mahara ana ahau ki nga ra onamata; e whakaaro ana ki au mahi katoa: e whakaaroaro ana ahau ki nga meatanga a ou ringa.
6 Èmi na ọwọ́ mi jáde sí ọ: òǹgbẹ rẹ gbẹ ọkàn mi bí i ìyàngbẹ ilẹ̀. (Sela)
Totoro tonu atu oku ringa ki a koe: e hiainu ana toku wairua ki a koe, ano he whenua mauiui. (Hera)
7 Dá mi lóhùn kánkán, Olúwa; ó rẹ ẹ̀mí mi tán. Má ṣe pa ojú rẹ mọ́ kúrò lára mi kí èmi má ba à dàbí àwọn tí ó lọ sínú ihò.
Hohoro te whakahoki kupu mai ki ahau, e Ihowa; ka hemo toku wairua: kei huna tou mata ki ahau; kei rite ahau ki te hunga e heke ana ki te poka.
8 Mú mi gbọ́ ìṣeun ìfẹ́ rẹ ní òwúrọ̀: nítorí ìwọ ni mo gbẹ́kẹ̀lé. Fi ọ̀nà tí èmi i bá rìn hàn mí, nítorí èmi gbé ọkàn mi sókè sí ọ.
Meinga kia rongo ahau ki tou aroha i te ata; e whakawhirinaki ana hoki ahau ki a koe: meinga kia matau ahau ki te ara e haere ai ahau; kua ara nei hoki toku wairua ki a koe.
9 Gbà mí kúrò lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi, Olúwa, nítorí èmi fi ara mi pamọ́ sínú rẹ.
Whakaorangia ahau, e Ihowa, i oku hoariri: ka kuhu nei ahau ki roto ki a koe.
10 Kọ́ mi láti ṣe ìfẹ́ rẹ, nítorí ìwọ ni Ọlọ́run mi jẹ́ kí ẹ̀mí rẹ dídára darí mi sí ilẹ̀ tí ó tẹ́jú.
Whakaakona ahau ki te mea i tau e pai ai; ko koe hoki toku Atua: he pai tou wairua; arahina ahau ki te whenua o te tika.
11 Nítorí orúkọ rẹ, Olúwa, sọ mi di ààyè; nínú òdodo rẹ, mú ọkàn mi jáde nínú wàhálà.
Whakahauorangia ahau, e Ihowa, he whakaaro ki tou ingoa; whakaarohia tou tika, ka whakaputa ake i toku wairua i roto i te pouri.
12 Nínú ìfẹ́ rẹ tí kì í kùnà, ké àwọn ọ̀tá mi kúrò, run gbogbo àwọn tí ń ni ọkàn mi lára, nítorí pé èmi ni ìránṣẹ́ rẹ.
Aroha mai hoki, a huna oku hoariri: whakangaromia katoatia ano nga kaitukino o toku wairua: he pononga hoki ahau nau.

< Psalms 143 >