< Psalms 141 >

1 Saamu ti Dafidi. Olúwa, èmi ké pè ọ́; yára wá sí ọ̀dọ̀ mi. Gbọ́ ohùn mi, nígbà tí mo bá ń ké pè ọ́.
Nkosi, ngiyakhala kuwe; phangisa uze kimi; beka indlebe elizwini lami lapho ngikhala kuwe.
2 Jẹ́ kí àdúrà mi ó wá sí iwájú rẹ bí ẹbọ tùràrí àti ìgbé ọwọ́ mi si òkè rí bí ẹbọ àṣálẹ́.
Umkhuleko wami kawumiswe njengempepha phambi kwakho, ukuphakanyiswa kwezandla zami njengomnikelo wakusihlwa.
3 Fi ẹ̀ṣọ́ ṣọ́ ẹnu mi, Olúwa: kí o sì máa pa ìlẹ̀kùn ètè mi mọ́.
Nkosi, bekela umlomo wami umlindi, gcina umnyango wendebe zami.
4 Má ṣe jẹ́ kí ọkàn mi fà sí ohun tí ń ṣe ibi, láti máa bá àwọn tí ń ṣiṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ búburú má sì ṣe jẹ́ kí èmi jẹ àdídùn wọn.
Ungaphenduleli inhliziyo yami entweni embi, ukuthi ngenze izenzo ezimbi kanye labantu abenza ububi, ngingadli ezibilibocweni zabo.
5 Jẹ́ kí olódodo lù mí, ìṣeun ni ó jẹ́: jẹ́ kí ó bá mi wí, ó jẹ́ òróró ní orí mi. Tí kì yóò fọ́ mi ní orí. Síbẹ̀ àdúrà mi wá láìsí ìṣe àwọn olùṣe búburú.
Olungileyo kangitshaye ethandwenilomusa, angisole; kuzakuba ngamafutha ekhanda, ikhanda lami kalingawali, ngoba lomkhuleko wami usezakuba sezinhluphekweni zabo.
6 A ó ju àwọn alákòóso sílẹ̀ láti bẹ̀bẹ̀ òkúta, àwọn ẹni búburú yóò kọ pé àwọn ọ̀rọ̀ mi dùn.
Abahluleli babo baphoselwa emaceleni edwala, bazakuzwa amazwi ami ngoba amnandi.
7 Wọn yóò wí pé, “Bí ẹni tí ó la aporo sórí ilẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni egungun wa tànkálẹ̀ ní ẹnu isà òkú.” (Sheol h7585)
Amathambo ethu ahlakazekile emlonyeni wengcwaba njengobandayo adabule emhlabathini. (Sheol h7585)
8 Ṣùgbọ́n ojú mi ń bẹ lára rẹ, Olúwa Olódùmarè; nínú rẹ̀ ni èmi ti rí ààbò, má ṣe fà mi fún ikú.
Kodwa amehlo ami akuwe, Jehova, Nkosi; ngithembele kuwe; ungawuchayi umphefumulo wami.
9 Pa mí mọ́ kúrò nínú okùn tí wọn ti dẹ sílẹ̀ fún mi, kúrò nínú ìkẹ́kùn àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀.
Ngigcina emandleni omjibila abangibekele wona, lezithiyo zabenzi bobubi.
10 Jẹ́ kí àwọn ẹni búburú ṣubú sínú àwọ̀n ara wọn, nígbà tí èmi bá kọjá lọ láìléwu.
Ababi kabawele emambuleni abo kanye, ngize ngidlule mina.

< Psalms 141 >