< Psalms 141 >

1 Saamu ti Dafidi. Olúwa, èmi ké pè ọ́; yára wá sí ọ̀dọ̀ mi. Gbọ́ ohùn mi, nígbà tí mo bá ń ké pè ọ́.
Herre! jeg har raabt til dig, skynd dig til mig, vend dine Øren til min Røst, naar jeg kalder paa dig.
2 Jẹ́ kí àdúrà mi ó wá sí iwájú rẹ bí ẹbọ tùràrí àti ìgbé ọwọ́ mi si òkè rí bí ẹbọ àṣálẹ́.
Lad min Bøn staa som et Røgelseoffer for dit Ansigt, mine Hænders Opløftelse som et Aftenmadoffer.
3 Fi ẹ̀ṣọ́ ṣọ́ ẹnu mi, Olúwa: kí o sì máa pa ìlẹ̀kùn ètè mi mọ́.
Herre! sæt Vagt for min Mund, tag Vare paa mine Læbers Dør.
4 Má ṣe jẹ́ kí ọkàn mi fà sí ohun tí ń ṣe ibi, láti máa bá àwọn tí ń ṣiṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ búburú má sì ṣe jẹ́ kí èmi jẹ àdídùn wọn.
Bøj ikke mit Hjerte til nogen ond Handel, til at bedrive Misgerninger i Ugudelighed i Samfund med Mænd, som øve Uret; og lad mig ikke æde af deres lækre Mad!
5 Jẹ́ kí olódodo lù mí, ìṣeun ni ó jẹ́: jẹ́ kí ó bá mi wí, ó jẹ́ òróró ní orí mi. Tí kì yóò fọ́ mi ní orí. Síbẹ̀ àdúrà mi wá láìsí ìṣe àwọn olùṣe búburú.
Lad en retfærdig slaa mig i Kærlighed og revse mig; mit Hoved skal ikke vise Hovedolien fra sig; thi min Bøn skal fremdeles møde hines Ondskab.
6 A ó ju àwọn alákòóso sílẹ̀ láti bẹ̀bẹ̀ òkúta, àwọn ẹni búburú yóò kọ pé àwọn ọ̀rọ̀ mi dùn.
Deres Dommere ere nedstyrtede i Klippens Favn; og de selv have hørt mine Ord, at de vare liflige.
7 Wọn yóò wí pé, “Bí ẹni tí ó la aporo sórí ilẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni egungun wa tànkálẹ̀ ní ẹnu isà òkú.” (Sheol h7585)
Som naar en pløjer og furer Jorden, saa ere vore Ben spredte ved Dødsrigets Svælg. (Sheol h7585)
8 Ṣùgbọ́n ojú mi ń bẹ lára rẹ, Olúwa Olódùmarè; nínú rẹ̀ ni èmi ti rí ààbò, má ṣe fà mi fún ikú.
Thi til dig, Herre, Herre! se mine Øjne hen; paa dig forlader jeg mig; giv ikke min Sjæl til Pris!
9 Pa mí mọ́ kúrò nínú okùn tí wọn ti dẹ sílẹ̀ fún mi, kúrò nínú ìkẹ́kùn àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀.
Bevar mig fra Snaren, som de have udstillet for mig, og fra deres Garn, som gøre Uret.
10 Jẹ́ kí àwọn ẹni búburú ṣubú sínú àwọ̀n ara wọn, nígbà tí èmi bá kọjá lọ láìléwu.
Lad de ugudelige falde i deres eget Garn, medens jeg derhos slipper forbi.

< Psalms 141 >