< Psalms 140 >

1 Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Olúwa, gbà mi lọ́wọ́ ọkùnrin búburú u nì, yọ mí lọ́wọ́ ọkùnrin ìkà a nì,
Hina Gode! Wadela: i hamosu dunu amola nimi bagade gegesu dunu da nama hasalasisa: besa: le, Dia na gaga: ma.
2 ẹni tí ń ro ìwà búburú ní inú wọn; nígbà gbogbo ni wọ́n ń rú ìjà sókè sí mi.
Ilia da eso huluane wadela: le hamomusa: ilegelala. Ilia da eso huluane sia: ga gegesa amola sia: waisa.
3 Wọ́n ti pọ́n ahọ́n wọn bí ejò, oró paramọ́lẹ̀ ń bẹ ní abẹ́ ètè wọn.
Ilia gona: su da medosu sania defele gala. Ilia sia: da saya: be ea medosu defo hano defele gala.
4 Olúwa, pa mí mọ́ kúrò lọ́wọ́ àwọn ènìyàn búburú; yọ mí kúrò lọ́wọ́ ọkùnrin ìkà a nì ẹni tí ó ti pinnu rẹ̀ láti bi ìrìn mi ṣubú.
Hina Gode! Wadela: i hamosu dunu ilia gasaga na banenesisa: besa: le, na gaga: ma. Nimi gegesu dunu da na dafama: ne ilegesa. Dia na gaga: ma!
5 Àwọn agbéraga ti dẹkùn sílẹ̀ fún mi àti okùn: wọ́n ti na àwọ̀n lẹ́bàá ọ̀nà; wọ́n ti kẹ́kùn sílẹ̀ fún mi.
Hidale gasa fibi dunu da na sa: ima: ne sanenesisi. Ilia da na gagulaligima: ne, logoba: le sanenesisu.
6 Èmi wí fún Olúwa pé ìwọ ni Ọlọ́run mi; Olúwa, gbọ́ ohùn ẹ̀bẹ̀ mi.
Na da Hina Godema amane sia: sa, “Di da na Gode! Hina Gode! Na fidima: ne digini wele sia: be nabima!
7 Olúwa Olódùmarè, agbára ìgbàlà mi, ìwọ ni ó bo orí mi mọ́lẹ̀ ní ọjọ́ ìjà.
Na ouligisudafa Hina Gode! Na gasa bagade Gaga: su Dunu! Dia da gegesu ganodini na gaga: i.
8 Olúwa, máa ṣe fi ìfẹ́ ènìyàn búburú fún un; má ṣe kún ọgbọ́n búburú rẹ̀ lọ́wọ́; kí wọn kí ó máa ba à gbé ara wọn ga. (Sela)
Hina Gode! Wadela: i hamosu dunu ilia hanai liligi ilima mae ima. Ilia wadela: i hamoma: ne ilegesu amo hedofama.
9 Bí ó ṣe ti orí àwọn tí ó yí mi káàkiri ni, jẹ́ kí ète ìka ara wọn kí ó bò wọ́n mọ́lẹ̀.
Na ha lai dunu da na hasalasisa: besa: le, ilia logo hedofama. Ilia nama se ima: ne sia: su da sinidigili, ilima se ima: ne, Dia hamoma.
10 A ó da ẹ̀yin iná sí wọn lára, Òun yóò wọ́ wọn lọ sínú iná, sínú ọ̀gbun omi jíjìn, kí wọn kí ó má ba à le dìde mọ́.
Gia: i bagade lalu oso da ili da: iya sa: imu da defea. Ilia da uli dogoi ganodini dafane, bu hame heda: mu da defea.
11 Má ṣe jẹ́ kí aláhọ́n búburú fi ẹsẹ̀ múlẹ̀ ní ayé; ibi ni yóò máa dọdẹ ọkùnrin ìkà nì láti bì í ṣubú.
Dunu amo da eno dunuma ogogole diwaneya udidisia, ilia hamobe da didili hame hamomu da defea. Dodona: gi gegesu dunu da wadela: su liligi amoga gugunufinisi dagoi ba: mu da defea.
12 Èmi mọ̀ pé, Olúwa yóò mú ọ̀nà olùpọ́njú dúró, yóò sì ṣe ẹ̀tọ́ fún àwọn tálákà.
Hina Gode! Na dawa: , Di da hame gagui dunu amola hahanibi dunu ilia hou gaga: sa.
13 Nítòótọ́ àwọn olódodo yóò máa fi ọpẹ́ fún orúkọ rẹ; àwọn ẹni dídúró ṣinṣin yóò máa gbé iwájú rẹ.
Moloidafa dunu ilia da Dima nodone sia: ne, Dia midadi esalumu.

< Psalms 140 >