< Psalms 14 >

1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Aṣiwèrè wí nínú ọkàn rẹ̀ pé, “Ko sí Ọlọ́run.” Wọ́n díbàjẹ́, iṣẹ́ wọn sì burú; kò sí ẹnìkan tí yóò ṣe rere.
Načelniku godbe; Davidova. Nespametni govori v srci svojem: Ni ga Boga: pohujšujejo, ostudna dela doprinašajo, ni ga, da bi delal dobro.
2 Olúwa sì bojú wolẹ̀ láti ọ̀run wá lórí àwọn ọmọ ènìyàn bóyá ó le rí ẹni tí òye yé, ẹnikẹ́ni tó ń wá Ọlọ́run.
Gospod gleda z nebes na sinove človeške, da bi videl, je li kateri, ki bi bil razumen, ki bi iskal Boga.
3 Gbogbo wọn sì ti yípadà, gbogbo wọn sì ti díbàjẹ́; kò sì ṣí ẹni tí ó ń ṣe rere, kò sí ẹnìkan.
Vsak je odstopil, izpridili so se vsi vkup; ni ga, da bi delal dobro, enega samega ne.
4 Ǹjẹ́ olùṣe búburú kò ha ní ìmọ̀? Àwọn tí ó ń pa ènìyàn mi jẹ bí ẹní jẹun; wọn kò sì ké pe Olúwa?
Ali si niso v svesti vsi, kateri delajo krivico, ker žró ljudstvo moje kruh jedóč, ne kličejo Gospoda?
5 Wọ́n wà níbẹ̀, tí a bò mọ́lẹ̀ pẹ̀lú ẹ̀rù, nítorí Ọlọ́run wà ní àwùjọ àwọn olódodo.
Tu se preplašijo od groze, ker Bog je na strani pravičnemu rodu.
6 Ẹ̀yin olùṣe búburú da èrò àwọn tálákà rú, ṣùgbọ́n Olúwa ni ààbò wọn.
Naklep siromaka ubozega bodete osramotili, seveda! ker Gospod je zavetje njegovo.
7 Ìgbàlà àwọn Israẹli yóò ti Sioni wá! Nígbà tí Olúwa bá mú ìkólọ àwọn ènìyàn rẹ̀ padà, jẹ́ kí Jakọbu kí ó yọ̀, kí inú Israẹli kí ó dùn!
Kdo naj dá rešenje sè Sijona Izraelu? Ko bode nazaj peljal iz sužnjosti ljudstva svojega krdelo, radoval se bode Jakob, veselil se Izrael.

< Psalms 14 >